1 Crônicas 16

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs VC

Sair da comparação
VC Versão Católica
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
1 Fizeram entrar a arca do Senhor e colocaram-na no meio do pavilhão que para ela Davi tinha levantado, e ofereceram a Deus holocaustos e sacrifícios pacíficos.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
2 Depois desse oferecimento de holocaustos e sacrifícios pacíficos, Davi abençoou o povo em nome do Senhor.
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
3 Em seguida, distribuiu a todos os israelitas, homens e mulheres, a cada um, um pão, um pedaço de carne, e um bolo de uvas secas.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
4 Davi colocou, diante da arca do Senhor, levitas encarregados do serviço, que invocavam, celebravam e louvavam o Senhor, Deus de Israel.
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
5 Eram eles: Asaf, o chefe; Zacarias, o segundo; em seguida, Oziel, Semiramot, Matatias, Eliab, Banaias, Obededom: Jeiel estava encarregado das harpas e das cítaras, enquanto que Asaf fazia vibrar os címbalos.
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
6 Os sacerdotes Banaias e Jaziel tocavam continuamente a trombeta diante da arca da aliança do Senhor.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
7 Foi naquele dia que Davi encarregou Asaf e seus irmãos de celebrar o Senhor:
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
8 Celebrai o Senhor, aclamai o seu nome, apregoai entre as nações as suas obras.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
9 Cantai-lhe hinos e cânticos, anunciai todas as suas maravilhas.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
10 Gloriai-vos do seu santo nome, rejubile o coração dos que procuram o Senhor.
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
11 Recorrei ao Senhor e ao seu poder, procurai continuamente sua face.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
12 Recordai as maravilhas que operou, seus prodígios e os julgamentos por seus lábios proferidos,
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
13 ó descendência de Israel, seu servo, ó filhos de Jacó, seus escolhidos!
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
14 É ele o Senhor, nosso Deus; suas sentenças comandam a terra inteira.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
15 Recordai sem cessar suas alianças, a palavra que empenhou a mil gerações,
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
16 que garantiu a Abraão e jurou a Isaac,
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
17 e confirmou a Jacó irrevogavelmente e a Israel como aliança eterna,
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
18 quando disse: Eu te darei a terra de Canaã, como parte da tua herança.
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
19 Quando não passavam de um reduzido número, minoria insignificante e estrangeiros na terra,
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
20 e andavam errantes de nação em nação, de reino em reino,
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
21 não permitiu que ninguém os oprimisse e castigou os reis por causa deles:
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;
22 Não ouseis tocar nos que me são consagrados nem maltratar os meus profetas!
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé;
23 Cantai ao Senhor, terra inteira, anunciai cada dia a salvação que ele nos trouxe.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
24 Proclamai às nações a sua glória, a todos os povos as suas maravilhas.
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ;
25 Porque o Senhor é grande e digno de todo o louvor, o único temível de todos os deuses,
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,
26 Porque os deuses dos povos, sejam quais forem, não passam de ídolos; mas foi o Senhor quem criou os céus.
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀;
27 Em seu semblante, a majestade e a beleza, em sua Morada, o poder e a felicidade.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,
28 Tributai ao Senhor, famílias dos povos, tributai ao Senhor a glória e a honra,
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;
29 tributai ao Senhor a glória devida ao seu nome. Trazei oferendas e chegai à sua presença, adorai o Senhor com ornamentos sagrados.
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!
30 Diante dele estremece a terra inteira e não vacila, porque ele a sustém.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn;
31 Alegrem-se os céus e exulte a terra, e confessem as nações: O Senhor é rei.
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀;
32 Retumbe o oceano e o que ele contém, regozijem-se os campos e tudo o que existe neles.
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,
33 Jubilem as árvores da floresta com a presença do Senhor, pois ele vem para governar a terra.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
34 Louvai o Senhor, porque ele é bom, porque a sua misericórdia é eterna.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa;
35 Dizei: Salvai-nos ó Deus de nossa salvação, e recolhei-nos e salvai-nos de entre as nações: para que possamos celebrar o vosso santo nome e ter a satisfação de vos louvar.
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,
36 Bendito seja o Senhor, Deus de Israel, pelos séculos dos séculos! E todo o povo disse: Amém! e Louvai o Senhor!
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
37 Davi deixou ali, diante da arca da aliança do Senhor, Asaf e seus irmãos para fazerem continuamente o serviço diante da arca, segundo o seu dever de cada dia;
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
38 igualmente Obededom, com seus irmãos, em número de sessenta e oito; Obededom, filho de Iditum, e Hosa, como porteiros;
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
39 igualmente o sacerdote Sadoc e os sacerdotes seus irmãos, diante do tabernáculo do Senhor, no lugar alto de Gabaon,
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
40 para oferecer holocaustos ao Senhor, dia a dia, pela manhã e pela tarde, sobre o altar dos holocaustos, e para cumprir tudo que está escrito na lei que o Senhor deu a Israel.
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
41 Com eles estavam Hemã, Iditum e os outros que tinham sido escolhidos e designados nominalmente para louvar o Senhor, porque sua misericórdia é eterna.
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
42 Tinham consigo trombetas e címbalos para tocar, e instrumentos para os cânticos de Deus. Os filhos de Iditum estavam encarregados da porta.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
43 Depois, todo o povo retornou para suas casas; e Davi voltou para abençoar sua casa.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.