1 Crônicas 16

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
1 Assim, eles trouxeram a arca de Deus, e a puseram no meio da tenda que Davi havia armado; e ofereceram sacrifícios queimados e ofertas de paz diante de Deus.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
2 E quando Davi havia terminado de oferecer as ofertas queimadas e as ofertas de paz, ele abençoou o povo em nome do SENHOR.
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
3 E ele repartiu para cada um de Israel, tanto homem, como mulher, um pão, e um bom pedaço de carne, e um frasco de vinho.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
4 E ele indicou alguns dos levitas para ministrarem diante da arca do SENHOR, para recordarem, para dar graças e louvores ao SENHOR Deus de Israel:
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
5 Asafe, o chefe, e depois dele Zacarias, Jeiel, e Semiramote, e Jeiel, e Matitias, e Eliabe, e Benaia, e Obede-Edom; e Jeiel, com saltérios e com harpas; porém Asafe fazia um som com címbalos;
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
6 também Benaia e Jaaziel, os sacerdotes, continuamente com trombetas diante da arca do pacto de Deus.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
7 Então, naquele dia, Davi entregou primeiro, na mão de Asafe e dos seus irmãos, este salmo para dar graças ao SENHOR.
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
8 Dai graças ao SENHOR, clamai o seu nome, fazei conhecidos os seus feitos entre os povos.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
9 Cantai a ele, cantai-lhe salmos, falai de todas as suas obras maravilhosas.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
10 Gloriai-vos no seu santo nome; que se regozije o coração daqueles que buscam o SENHOR.
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
11 Buscai o SENHOR e a sua força, buscai a sua face continuamente.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
12 Lembrai-vos das obras maravilhosas que ele tem feito, das suas maravilhas, e dos juízos da sua boca.
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
13 Vós, semente de Israel, o seu servo, vós filhos de Jacó, os seus escolhidos.
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
14 Ele é o SENHOR nosso Deus; os seus juízos estão em toda a terra.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
15 Estejais sempre atentos ao seu pacto; a palavra que ele ordenou a mil gerações;
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
16 a saber, do pacto que ele celebrou com Abraão, e do seu juramento a Isaque;
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
17 e tem confirmado o mesmo a Jacó por uma lei, e a Israel por um pacto eterno,
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
18 dizendo: A ti darei a terra de Canaã, a porção da tua herança.
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
19 Quando éreis nada mais que poucos, de fato poucos, e estrangeiros nela,
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
20 e quando eles andavam de nação em nação, e de um reino para outro povo.
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
21 Ele não tolerou que homem algum lhe fizesse o mal; sim, reprovou reis por causa deles,
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;
22 dizendo: Não toqueis nos meus ungidos, e não façais mal algum aos meus profetas.
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé;
23 Cantai ao SENHOR, toda a terra; proclamai dia após dia a sua salvação.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
24 Declarai a sua glória no meio dos pagãos; suas obras maravilhosas no meio de todas as nações.
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ;
25 Porque grande é o SENHOR e poderosíssimo para ser louvado; ele também deve ser temido acima de todos os deuses.
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,
26 Porque todos os deuses do povo são ídolos; porém o SENHOR fez os céus.
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀;
27 Glória e honra estão na sua presença; força e alegria estão no seu lugar.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,
28 Dai ao SENHOR, vós parentes do povo, dai ao SENHOR glória e força.
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;
29 Dai ao SENHOR a glória devida ao seu nome; trazei uma oferta, e vinde diante dele; adorai ao SENHOR na beleza da santidade.
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!
30 Temei diante dele, toda a terra; o mundo se acha firmado, de modo que não será movido.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn;
31 Que os céus se alegrem, e que a terra se regozije; e que os homens digam no meio das nações: o SENHOR reina.
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀;
32 Que ruja o mar, e a sua plenitude; que os campos se regozijem, e tudo o que está neles.
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,
33 Então, as árvores do bosque cantarão diante da presença do SENHOR, porque ele vem julgar a terra.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
34 Dai graças ao SENHOR; porque ele é bom; pois a sua misericórdia dura para sempre.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa;
35 E dizei: Salva-nos, ó Deus da nossa salvação, e ajunta-nos, e nos livra dos pagãos, para que possamos dar graças ao teu nome santo, e glória em teu louvor.
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,
36 Bendito seja o SENHOR Deus de Israel para sempre e sempre. E todo o povo disse: Amém, e louvou ao SENHOR.
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
37 Assim, ele deixou ali diante da arca do pacto do SENHOR, Asafe e os seus irmãos, para ministrarem continuamente diante da arca, como exigia a tarefa de cada dia;
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
38 e Obede-Edom, com os seus irmãos, sessenta e oito; também Obede-Edom, o filho de Jedutum, e Hosa para serem porteiros;
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
39 e Zadoque, o sacerdote, e os seus irmãos, os sacerdotes, diante do tabernáculo do SENHOR no lugar alto que ficava em Gibeão,
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
40 para oferecerem ofertas queimadas continuamente ao SENHOR sobre o altar da oferta queimada, pela manhã e ao entardecer, e para fazerem segundo tudo o que está escrito na lei do SENHOR, a qual ele ordenou a Israel;
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
41 e com eles Hemã e Jedutum, e os demais que foram escolhidos, que foram designados por nome, para darem graças ao SENHOR, pois a sua misericórdia dura para sempre;
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
42 e com eles Hemã e Jedutum, com trombetas e címbalos para aqueles que fariam um som, e com instrumentos musicais de Deus. E os filhos de Jedutum eram porteiros.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
43 E todo o povo partiu, cada homem, para a sua casa; e Davi retornou para abençoar a sua casa.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.