1 Crônicas 16

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH

Sair da comparação
NTLH Nova Tradução na Linguagem de Hoje 2000
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
1 Levaram a arca da aliança para a barraca que Davi tinha preparado para ela e a colocaram lá dentro. Então ofereceram a Deus sacrifícios que foram completamente queimados e ofertas de paz.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
2 Depois que Davi acabou de oferecer os sacrifícios, abençoou o povo em nome do Senhor
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
3 e distribuiu comida a todos. Deu a cada homem e a cada mulher de Israel um pão, um pedaço de carne assada e passas.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
4 Davi nomeou alguns levitas para dirigirem a adoração ao Senhor , o Deus de Israel, cantando e louvando a Deus, em frente da arca da aliança.
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
5 Asafe foi nomeado o chefe deles, e Zacarias, o seu ajudante. Para tocarem lira , foram nomeados: Jeiel, Semiramote, Jeiel, Matitias, Eliabe, Benaías, Obede-Edom e Jeiel. Para tocar pratos, foi nomeado Asafe,
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
6 e, para tocarem trombeta todos os dias em frente da arca da aliança, foram nomeados os sacerdotes Benaías e Jaaziel.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
7 Foi nesse dia que Davi deu pela primeira vez a Asafe e aos seus colegas levitas a responsabilidade de cantarem louvores a Deus, o Senhor .
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
8 Agradeçam a Deus, o Senhor , anunciem a sua grandeza e contem às nações as coisas que ele fez.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
9 Cantem a Deus, cantem louvores a ele, falem dos seus atos maravilhosos.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
10 Tenham orgulho daquilo que o Santo Deus tem feito. Que fique alegre o coração de todos os que adoram ao
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
11 Procurem a ajuda do Senhor ; estejam sempre na sua presença. vocês, descendentes de Jacó, o escolhido de Deus, lembrem de tudo o que Deus tem feito, lembrem dos seus grandes e maravilhosos milagres e de como tem condenado os nossos inimigos!
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
12 — ausente —
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
13 — ausente —
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
14 Ele é o Senhor , nosso Deus; os seus mandamentos são para o mundo inteiro.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
15 Ele sempre lembrará da sua aliança e, por milhares de
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
16 Ele será fiel à aliança feita com Abraão e à promessa que fez com juramento a Isaque.
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
17 Deus fez uma aliança com Jacó para sempre, fez com ele uma aliança eterna.
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
18 Naquela ocasião Deus disse: “Eu lhe darei a terra de Canaã, e ela será de vocês para sempre.”
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
19 Eles eram muito poucos, eram estrangeiros na
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
20 Andavam de país em país, de reino em reino.
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
21 Mas Deus não deixou que ninguém os maltratasse e, para protegê-los, avisou reis.
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;
22 Ele disse: “Não toquem nos servos que eu escolhi; não maltratem os meus
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé;
23 Cantem ao Senhor , todos os povos da terra. Anunciem todos os dias que ele nos salvou.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
24 Falem da sua glória às nações; contem a todos os povos as coisas maravilhosas que ele tem feito.
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ;
25 O Senhor é grande e merece todo o nosso louvor; ele deve ser
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,
26 Pois os deuses das outras nações são somente ídolos, mas o
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀;
27 Ele está cercado de glória e majestade; poder e beleza enchem o seu Templo.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,
28 Louvem o Senhor , todos os povos da terra! Louvem a sua glória e o seu poder.
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;
29 Deem ao Senhor a honra que ele merece; tragam uma oferta e entrem nos pátios do seu Templo. Curvem-se diante do Santo Deus quando ele aparecer;
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!
30 trema diante dele, toda a terra. A terra está firme no seu lugar e não pode ser abalada.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn;
31 Alegre-se a terra, e fique contente o céu. Digam em todas as nações: “O
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀;
32 Ruja o mar e todas as criaturas que nele vivem. Alegrem-se os campos e tudo o que há neles.
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,
33 Então as árvores dos bosques gritarão de alegria diante de Deus, o Senhor , pois ele vem governar a terra.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
34 Deem graças ao Senhor porque ele é bom, e o seu amor dura para sempre.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa;
35 Digam a ele: “Liberta-nos, ó Senhor , nosso Salvador! Ajunta-nos e tira-nos do meio dos pagãos. Assim nós te daremos graças e com prazer te louvaremos, ó Santo Deus.”
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,
36 Louvemos o Senhor , o Deus de Israel. Louvem o Então todo o povo disse “
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
37 O rei Davi pôs Asafe e os seus colegas levitas como encarregados permanentes da adoração que era feita no lugar onde a arca da aliança havia sido colocada. Eles deviam cumprir ali os seus deveres todos os dias.
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
38 Obede-Edom, filho de Jedutum, e sessenta e oito homens do seu grupo de famílias deviam ser os seus ajudantes. Hosa e Obede-Edom eram os guardas dos portões.
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
39 Porém o sacerdote Zadoque e os seus colegas estavam encarregados do culto ao Senhor Deus na Tenda Sagrada , que estava no lugar de adoração em Gibeão.
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
40 Todas as manhãs e todas as tardes eles deviam oferecer no altar sacrifícios que seriam completamente queimados, de acordo com o que está escrito na Lei que o Senhor deu ao povo de Israel.
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
41 Estavam ali com eles Hemã e Jedutum e os outros que haviam sido nomeados a fim de cantar louvores ao Senhor por causa do seu amor que dura para sempre.
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
42 Hemã e Jedutum também estavam encarregados das trombetas, dos pratos e dos outros instrumentos que eram tocados para acompanhar os hinos de louvor. Os membros do grupo de famílias de Jedutum estavam encarregados de guardar os portões.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
43 Então todos foram para casa, e Davi também foi, a fim de passar algum tempo com a sua família.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.