1 Crônicas 16
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARIB
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
1 Trouxeram, pois, a arca de Deus e a colocaram no meio da tenda que Davi lhe tinha armado; e ofereceram holocaustos e sacrifícios pacíficos perante Deus.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
2 Tendo Davi acabado de oferecer os holocaustos e sacrifícios pacíficos, abençoou o povo em nome do Senhor.
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
3 Então repartiu a todos em Israel, tanto a homens como a mulheres, a cada um, um pão, um pedaço de carne e um bolo de passas.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
4 Também designou alguns dos levitas por ministros perante a arca do Senhor, para celebrarem, e para agradecerem e louvarem ao Senhor Deus de Israel, a saber:
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
5 Asafe, o chefe, e Zacarias, o segundo depois dele; Jeiel, Semiramote, Jeiel, Matitias, Eliabe, Benaías, Obede-Edom e Jeiel, com alaúdes e com harpas; e Asafe se fazia ouvir com címbalos;
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
6 e Benaías e Jaaziel, os sacerdotes, tocavam trombetas continuamente perante a arca do pacto de Deus.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
7 Foi nesse mesmo dia que Davi, pela primeira vez, ordenou que pelo ministério de Asafe e de seus irmãos se dessem ações de graças ao Senhor, nestes termos:
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
8 Louvai ao Senhor, invocai o seu nome; fazei conhecidos entre os povos os seus feitos.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
9 Cantai-lhe, salmodiai-lhe, falai de todas as suas obras maravilhosas.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
10 Gloriai-vos no seu santo nome; alegre-se o coração dos que buscam ao Senhor.
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
11 Buscai ao Senhor e a sua força; buscai a sua face continuamente.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
12 Lembrai-vos das obras maravilhosas que ele tem feito, dos seus prodígios, e dos juízos da sua boca,
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
13 vós, descendência de Israel, seus servos, vós, filhos de Jacó, seus eleitos.
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
14 Ele é o Senhor nosso Deus; em toda a terra estão os seus juízos.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
15 Lembrai-vos perpetuamente do seu pacto, da palavra que prescreveu para mil gerações;
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
16 do pacto que fez com Abraão, do seu juramento a Isaque,
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
17 o qual também a Jacó confirmou por estatuto, e a Israel por pacto eterno,
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
18 dizendo: A ti te darei a terra de Canaã, quinhão da vossa herança.
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
19 Quando eram poucos em número, sim, mui poucos, e estrangeiros na terra,
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
20 andando de nação em nação, e dum reino para outro povo,
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
21 a ninguém permitiu que os oprimisse, e por amor deles repreendeu reis,
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;
22 dizendo: Não toqueis os meus ungidos, e não façais mal aos meus profetas.
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé;
23 Cantai ao Senhor em toda a terra; proclamai de dia em dia a sua salvação.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
24 Publicai entre as nações a sua gloria, entre todos os povos as suas maravilhas.
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ;
25 Porque grande é o Senhor, e mui digno de louvor; também é mais temível do que todos os deuses.
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,
26 Pois todos os deuses dos povos são ídolos, porém o Senhor fez os céus.
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀;
27 Diante dele há honra e majestade; há força e alegria no seu lugar.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,
28 Tributai ao Senhor, ó famílias dos povos, tributai ao Senhor glória e força.
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;
29 Tributai ao Senhor a glória devida ao seu nome; trazei presentes, e vinde perante ele; adorai ao Senhor vestidos de trajes santos.
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!
30 Trema diante dele toda a terra; o mundo se acha firmado, de modo que se não pode abalar.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn;
31 Alegre-se o céu, e regozije-se a terra; e diga-se entre as nações: O Senhor reina.
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀;
32 Brama o mar e a sua plenitude; exulte o campo e tudo o que nele há;
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,
33 então jubilarão as árvores dos bosques perante o Senhor, porquanto vem julgar a terra.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
34 Dai graças ao Senhor, porque ele é bom; porque a sua benignidade dura para sempre.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa;
35 E dizei: Salva-nos, ó Deus da nossa salvação, e ajunta-nos, e livra-nos das nações, para que demos graças ao teu santo nome, e exultemos no teu louvor.
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,
36 Bendito seja o Senhor Deus de Israel, de eternidade a eternidade. Então todo o povo disse: Amém! e louvou ao Senhor.
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
37 Davi, pois, deixou ali, diante da arca do pacto do Senhor, Asafe e seus irmãos, para ministrarem continuamente perante a arca, segundo a exigência de cada dia.
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
38 Também deixou Obeede-Edom , com seus irmãos, sessenta e oito; Obede-Edomsa filho de Jedútum e Hosa, para serem porteiros;
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
39 e deixou Zadoque, o sacerdote, e seus irmãos, os sacerdotes, diante do tabernáculo do Senhor, no alto que havia em Gibeão,
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
40 para oferecerem holocaustos ao Senhor continuamente, pela manhã e à tarde, sobre o altar dos holocaustos; e isto segundo tudo o que está escrito na lei que o Senhor tinha ordenado a Israel;
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
41 e com eles Hemã, e Jedútum e os demais escolhidos, que tinham sido nominalmente designados, para darem graças ao Senhor, porque a sua benignidade dura para sempre.
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
42 Estavam Hemã e Jedútun encarregados das trombetas e dos címbalos para os que os haviam de tocar, e dos outros instrumentos para os cânticos de Deus; e os filhos de Jedútun estavam à porta.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
43 Então todo o povo se retirou, cada um para a sua casa; e Davi voltou para abençoar a sua casa.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.