1 Crônicas 16

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARC

Sair da comparação
ARC Almeida Revista e Corrigida 2009
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
1 Trazendo, pois, a arca de Deus, a puseram no meio da tenda que Davi lhe tinha armado; e ofereceram holocaustos e sacrifícios pacíficos perante Deus.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
2 E, acabando Davi de oferecer os holocaustos e sacrifícios pacíficos, abençoou o povo em nome do Senhor .
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
3 E repartiu a todos em Israel, tanto a homens como a mulheres, a cada um um pão, e um bom pedaço de carne, e um frasco de vinho.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
4 E pôs perante a arca do Senhor alguns dos levitas por ministros; e isso para recordarem, e louvarem, e celebrarem ao Senhor , Deus de Israel.
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
5 Era Asafe o chefe, e Zacarias, o segundo, e depois dele Jeiel, e Semiramote, e Jeiel, e Matitias, e Eliabe, e Benaia, e Obede-Edom, e Jeiel, com alaúdes e com harpas; e Asafe se fazia ouvir com címbalos.
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
6 Também Benaia e Jaaziel, os sacerdotes, estavam continuamente com trombetas, perante a arca do concerto de Deus.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
7 Então, naquele mesmo dia, entregou Davi em primeiro lugar o Salmo seguinte, para louvarem ao Senhor , pelo ministério de Asafe e de seus irmãos:
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
8 Louvai ao Senhor , invocai o seu nome, fazei conhecidos entre os povos os seus feitos.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
9 Cantai-lhe, salmodiai-lhe, atentamente falai de todas as suas maravilhas.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
10 Gloriai-vos no seu santo nome; alegre-se o coração dos que buscam o Senhor .
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
11 Buscai o Senhor e a sua força; buscai a sua face continuamente.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
12 Lembrai-vos das suas maravilhas que tem feito, dos seus prodígios, e dos juízos da sua boca.
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
13 Vós, semente de Israel, seus servos, vós, filhos de Jacó, seus eleitos.
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
14 Ele é o Senhor , nosso Deus; em toda a terra estão os seus juízos.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
15 Lembrai-vos perpetuamente do seu concerto e da palavra que prescreveu para mil gerações;
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
16 do concerto que fez com Abraão e do seu juramento a Isaque;
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
17 o qual também a Jacó ratificou por estatuto, e a Israel, por concerto eterno,
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
18 dizendo: A ti te darei a terra de Canaã, quinhão da vossa herança.
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
19 Sendo vós em pequeno número, poucos homens, e estrangeiros nela;
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
20 andavam de nação em nação e de um reino para outro povo.
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
21 A ninguém permitiu que os oprimisse e, por amor deles, repreendeu reis, dizendo:
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;
22 Não toqueis os meus ungidos e aos meus profetas não façais mal.
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé;
23 Cantai ao Senhor em toda a terra; anunciai de dia em dia a sua salvação.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
24 Contai entre as nações a sua glória, entre todos os povos as suas maravilhas.
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ;
25 Porque grande é o Senhor , e mui digno de ser louvado, e mais tremendo é do que todos os deuses.
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,
26 Porque todos os deuses das nações são vaidades; porém o Senhor fez os céus.
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀;
27 Majestade e esplendor há diante dele, força e alegria, no seu lugar.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,
28 Dai ao Senhor , ó famílias das nações, dai ao Senhor glória e força.
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;
29 Dai ao Senhor a glória de seu nome; trazei presentes e vinde perante ele; adorai ao Senhor na beleza da sua santidade.
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!
30 Trema perante ele, trema toda a terra; pois o mundo se firmará, para que se não abale.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn;
31 Alegrem-se os céus, e regozije-se a terra; e diga-se entre as nações: O Senhor reina.
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀;
32 Brama o mar com a sua plenitude; exulte o campo com tudo o que há nele.
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,
33 Então, jubilarão as árvores dos bosques perante o Senhor ; porquanto vem a julgar a terra.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
34 Louvai ao Senhor , porque é bom; pois a sua benignidade dura perpetuamente.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa;
35 E dizei: Salva-nos, ó Deus da nossa salvação, e ajunta-nos, e livra-nos das nações; para que louvemos o teu santo nome e nos gloriemos no teu louvor.
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,
36 Louvado seja o Senhor , Deus de Israel, de século em século. E todo o povo disse: Amém! E louvou ao Senhor .
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
37 Então, Davi deixou ali, diante da arca do concerto do Senhor , a Asafe e a seus irmãos, para ministrarem continuamente perante a arca, segundo se ordenara para cada dia.
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
38 E mais a Obede-Edom, com seus irmãos, sessenta e oito; a este Obede-Edom, filho de Jedutum, e a Hosa, ordenou por porteiros.
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
39 E mais a Zadoque, o sacerdote, e a seus irmãos, os sacerdotes, diante do tabernáculo do Senhor , no alto que estava em Gibeão,
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
40 para oferecerem ao Senhor os holocaustos sobre o altar dos holocaustos continuamente pela manhã e à tarde; e isso segundo tudo o que está escrito na Lei que o Senhor tinha prescrito a Israel.
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
41 E com eles deixou a Hemã, e a Jedutum, e aos mais escolhidos, que foram apontados pelos seus nomes, para louvarem ao Senhor , porque a sua benignidade dura perpetuamente.
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
42 Com eles, pois, estavam Hemã, e Jedutum, e trombetas, e címbalos para os que os faziam ouvir, e instrumentos de música de Deus; porém os filhos de Jedutum estavam à porta.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
43 Então, se foi todo o povo, cada um para a sua casa; e tornou Davi, para abençoar a sua casa.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.