1 Crônicas 16
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NVI
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
1 Eles trouxeram a arca de Deus e a colocaram na tenda que Davi lhe havia preparado, e ofereceram holocaustos e sacrifícios de comunhão diante de Deus.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
2 Após oferecer os holocaustos e os sacrifícios de comunhão, Davi abençoou o povo em nome do Senhor,
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
3 e deu um pão, um bolo de tâmaras e um bolo de uvas passas a cada homem e a cada mulher israelita.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
4 Davi nomeou alguns dos levitas para ministrarem diante da arca do Senhor, fazendo petições, dando graças, e louvando o Senhor, o Deus de Israel.
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
5 Desses, Asafe era o chefe, Zacarias vinha em seguida, e depois Jeiel, Semiramote, Jeiel, Matitias, Eliabe, Benaia, Obede-Edom e Jeiel. Eles deviam tocar lira e harpa, enquanto Asafe tocava os címbalos.
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
6 Os sacerdotes Benaia e Jaaziel deviam tocar diariamente as trombetas diante da arca da aliança de Deus.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
7 Foi naquele dia que pela primeira vez Davi encarregou a Asafe e seus parentes de louvar ao Senhor com salmos de gratidão:
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
8 Dêem graças ao Senhor, clamem pelo seu nome, divulguem entre as nações o que ele tem feito.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
9 Cantem para ele, louvem-no; contem todos os seus atos maravilhosos.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
10 Gloriem-se no seu santo nome; alegrem-se os corações dos que buscam o Senhor.
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
11 Olhem para o Senhor e para a sua força; busquem sempre a sua face.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
12 Lembrem-se das maravilhas que ele fez, dos seus prodígios e das ordenanças que pronunciou,
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
13 ó descendentes de Israel, seu servo, ó filhos de Jacó, seus escolhidos.
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
14 Ele é o Senhor, o nosso Deus; seus domínio alcança toda a terra.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
15 Para sempre se lembra da sua aliança, da palavra que ordenou para mil gerações,
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
16 da aliança que fez com Abraão, do juramento que fez a Isaque,
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
17 que confirmou para Jacó como um decreto, e para Israel como uma aliança eterna, dizendo:
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
18 "A vocês darei a terra de Canaã, a herança que possuirão".
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
19 Quando eles ainda eram poucos, muito poucos, e estrangeiros nela,
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
20 e vagueavam de nação em nação, de um reino a outro,
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
21 ele não permitiu que ninguém os oprimisse; por causa deles repreendeu reis, ordenando:
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;
22 "Não maltratem os meus ungidos; não façam mal aos meus profetas".
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé;
23 Cantem ao Senhor, todas as terras! Proclamem a sua salvação dia após dia!
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
24 Anunciem a sua glória entre as nações, seus feitos maravilhosos entre todos os povos!
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ;
25 Pois o Senhor é grande e muitíssimo digno de louvor; ele deve ser mais temido que todos os deuses.
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,
26 Pois todos os deuses das nações não passam de ídolos, mas o Senhor fez os céus.
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀;
27 O esplendor e a majestade estão diante dele; força e alegria na sua habitação.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,
28 Dêem ao Senhor, ó famílias das nações, dêem ao Senhor glória e força.
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;
29 Dêem ao Senhor a glória devida ao seu nome. Tragam ofertas e venham à sua presença. Adorem o Senhor no esplendor da sua santidade,
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!
30 tremam diante dele, todas as nações! Firmou o mundo, que não se abalará!
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn;
31 Que os céus se alegrem e a terra exulte, e diga-se entre as nações: "O Senhor reina! "
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀;
32 Ressoe o mar, e tudo o que nele existe; exultem os campos, e tudo o que neles há!
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,
33 Então as árvores da floresta cantarão de alegria, cantarão diante do Senhor, pois ele vem julgar a terra.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
34 Rendam graças ao Senhor, pois ele é bom; o seu amor dura para sempre.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa;
35 Clamem: "Salva-nos, ó Deus, nosso Salvador! Reúne-nos e livra-nos das nações, para que demos graças ao teu santo nome e façamos do teu louvor a nossa glória".
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,
36 Bendito seja o Senhor, o Deus de Israel, de eternidade a eternidade. Então todo o povo exclamou: "Amém! " e "Louvado seja o Senhor! "
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
37 Então Davi deixou Asafe e seus parentes diante da arca da aliança do Senhor para ali ministrarem regularmente, de acordo com as prescrições para cada dia.
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
38 Também deixou Obede-Edom e seus sessenta e oito parentes para ministrarem com eles. Obede-Edom, filho de Jedutum, e também Hosa foram porteiros.
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
39 Davi deixou o sacerdote Zadoque e seus parentes sacerdotes diante do tabernáculo do Senhor em Gibeom
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
40 para regularmente, de manhã e à tarde, apresentarem holocaustos no altar de holocaustos, de acordo com tudo o que está escrito na Lei do Senhor, que ele deu a Israel.
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
41 Com eles estavam Hemã e Jedutum e os outros designados para darem graças ao Senhor, exclamando: "O seu amor dura para sempre".
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
42 Hemã e Jedutum eram responsáveis pelas trombetas, pelos címbalos e pelos outros instrumentos musicais para o culto. Os filhos de Jedutum foram designados como porteiros.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
43 Então todo o povo partiu, cada um para a sua casa, e Davi voltou para casa para abençoar sua família.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.