1 Crônicas 16
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NVT
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
1 Trouxeram a arca de Deus e a colocaram dentro da tenda especial que Davi tinha preparado para ela. Em seguida, apresentaram a Deus holocaustos e ofertas de paz.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
2 Quando Davi terminou de oferecer os holocaustos e ofertas de paz, abençoou o povo em nome do S enhor .
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
3 Depois, para cada homem e mulher em todo o Israel, deu um pão, um bolo de tâmaras e um bolo de passas.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
4 Davi nomeou os seguintes levitas para servirem diante da arca do S enhor , invocarem as bênçãos dele e darem graças e louvarem o S enhor , o Deus de Israel:
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
5 Asafe, o chefe do grupo, tocava os címbalos. Depois dele vinha Zacarias, seguido de Jeiel, Semiramote, Jeiel, Matitias, Eliabe, Benaia, Obede-Edom e Jeiel, que tocavam harpas e liras.
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
6 Os sacerdotes Benaia e Jaaziel tocavam trombetas continuamente diante da arca da aliança de Deus.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
7 Naquele dia, Davi encarregou Asafe e seus parentes levitas de louvarem com ação de graças ao S enhor :
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
8 “Deem graças ao S enhor e proclamem seu nome, anunciem entre os povos o que ele tem feito.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
9 Cantem a ele, sim, cantem louvores a ele, falem a todos de suas maravilhas.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
10 Exultem em seu santo nome, alegrem-se todos que buscam o S
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
11 Busquem o S enhor e sua força, busquem sua presença todo o tempo.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
12 Lembrem-se das maravilhas que ele fez, dos milagres que realizou e dos juízos que pronunciou,
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
13 vocês que são filhos de seu servo Israel, descendentes de Jacó, seus escolhidos.
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
14 “Ele é o S enhor , nosso Deus; vemos sua justiça em toda a terra.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
15 Lembrem-se de sua aliança para sempre, do compromisso que ele firmou com mil gerações.
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
16 É a aliança que fez com Abraão, o juramento que fez a Isaque.
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
17 Ele a confirmou a Jacó por decreto, ao povo de Israel como aliança sem fim:
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
18 ‘Darei a vocês a terra de Canaã, como a porção de sua herança’.
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
19 “Assim declarou quando vocês ainda eram poucos, um punhado de estrangeiros em Canaã.
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
20 Vagaram de uma nação a outra, de um reino a outro.
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
21 E, no entanto, ele não permitiu que ninguém os oprimisse e, em seu favor, repreendeu reis:
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;
22 ‘Não toquem em meu povo escolhido, não façam mal a meus profetas’.
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé;
23 “Toda a terra cante ao S enhor ! Proclamem todos os dias a sua salvação.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
24 Anunciem a sua glória entre as nações, contem a todos as suas maravilhas.
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ;
25 Grande é o S enhor ! Digno de muito louvor! Ele é mais temível que todos os deuses.
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,
26 Os deuses de outros povos não passam de ídolos, mas o S
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀;
27 Glória e majestade o cercam, força e alegria enchem sua habitação.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,
28 “Ó nações do mundo, reconheçam o S enhor , reconheçam que o S
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;
29 Deem ao S enhor a glória que seu nome merece, tragam ofertas e venham à sua presença. Adorem o S
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!
30 toda a terra trema diante dele. O mundo permanece firme e não pode ser abalado.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn;
31 “Alegrem-se os céus e exulte a terra! Digam entre as nações: ‘O S
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀;
32 Deem louvor o mar e tudo que nele há! Os campos e suas colheitas gritem de alegria!
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,
33 As árvores do bosque exultem diante do S enhor , pois ele vem para julgar a terra.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
34 “Deem graças ao S enhor , porque ele é bom; seu amor dura para sempre!
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa;
35 Clamem: ‘Salva-nos, ó Deus de nossa salvação! Reúne-nos e livra-nos das nações, para darmos graças ao teu santo nome, para nos alegrarmos no teu louvor’.
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,
36 “Louvem o S enhor , o Deus de Israel, que vive de eternidade a eternidade!”. Todo o povo disse em alta voz: “Amém!” e louvou o S
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
37 Davi providenciou que Asafe e seus parentes levitas servissem continuamente diante da arca da aliança do S enhor e cumprissem seus deveres de cada dia.
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
38 Faziam parte desse grupo: Obede-Edom, filho de Jedutum, Hosa e 68 levitas que eram guardas das portas.
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
39 Enquanto isso, Davi deixou o sacerdote Zadoque e seus parentes no tabernáculo do S enhor , no lugar de adoração em Gibeom, onde continuaram a servir diante do S enhor .
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
40 Todas as manhãs e todas as tardes, ofereciam holocaustos ao S enhor no altar separado para essa finalidade, em obediência a tudo que estava escrito na lei do S enhor , conforme ele tinha ordenado a Israel.
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
41 Davi também designou Hemã, Jedutum e outros escolhidos por nome para darem graças ao S enhor , pois “seu amor dura para sempre”.
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
42 Acompanhavam os cânticos de louvor a Deus com trombetas, címbalos e outros instrumentos. Os filhos de Jedutum foram nomeados guardas das portas.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
43 Então todos voltaram para casa, e Davi também voltou para abençoar sua família.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.