1 Crônicas 16

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARA

Sair da comparação
ARA Almeida Revista e Atualizada 1993
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
1 Introduziram, pois, a arca de Deus e a puseram no meio da tenda que lhe armara Davi; e trouxeram holocaustos e ofertas pacíficas perante Deus.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
2 Tendo Davi acabado de trazer os holocaustos e ofertas pacíficas, abençoou o povo em nome do Senhor .
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
3 E repartiu a todos em Israel, tanto os homens como as mulheres, a cada um, um bolo de pão, um bom pedaço de carne e passas.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
4 Designou dentre os levitas os que haviam de ministrar diante da arca do Senhor , e celebrar, e louvar, e exaltar o Senhor , Deus de Israel, a saber,
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
5 Asafe, o chefe, Zacarias, o segundo, e depois Jeiel, Semiramote, Jeiel, Matitias, Eliabe, Benaia, Obede-Edom e Jeiel, com alaúdes e harpas; e Asafe fazia ressoar os címbalos.
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
6 Os sacerdotes Benaia e Jaaziel estavam continuamente com trombetas, perante a arca da Aliança de Deus.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
7 Naquele dia, foi que Davi encarregou, pela primeira vez, a Asafe e a seus irmãos de celebrarem com hinos o Senhor .
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
8 Rendei graças ao Senhor , invocai o seu nome, fazei conhecidos, entre os povos, os seus feitos.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
9 Cantai-lhe, cantai-lhe salmos; narrai todas as suas maravilhas.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
10 Gloriai-vos no seu santo nome; alegre-se o coração dos que buscam o
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
11 Buscai o Senhor e o seu poder, buscai perpetuamente a sua presença.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
12 Lembrai-vos das maravilhas que fez, dos seus prodígios e dos juízos dos seus lábios,
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
13 vós, descendentes de Israel, seu servo, vós, filhos de Jacó, seus escolhidos.
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
14 Ele é o Senhor , nosso Deus; os seus juízos permeiam toda a terra.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
15 Lembra-se perpetuamente da sua aliança, da palavra que empenhou para mil gerações;
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
16 da aliança que fez com Abraão e do juramento que fez a Isaque;
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
17 o qual confirmou a Jacó por decreto e a Israel, por aliança perpétua,
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
18 dizendo: Dar-vos-ei a terra de Canaã como quinhão da vossa herança.
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
19 Então, eram eles em pequeno número, pouquíssimos e forasteiros nela;
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
20 andavam de nação em nação, de um reino para um povo.
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
21 A ninguém permitiu que os oprimisse; antes, por amor deles, repreendeu a reis,
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;
22 dizendo: Não toqueis nos meus ungidos, nem maltrateis os meus profetas.
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé;
23 Cantai ao Senhor , todas as terras; proclamai a sua salvação, dia após dia.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
24 Anunciai entre as nações a sua glória, entre todos os povos, as suas maravilhas,
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ;
25 porque grande é o Senhor e mui digno de ser louvado, temível mais do que todos os deuses.
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,
26 Porque todos os deuses dos povos são ídolos; o
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀;
27 Glória e majestade estão diante dele, força e formosura, no seu santuário.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,
28 Tributai ao Senhor , ó famílias dos povos, tributai ao
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;
29 Tributai ao Senhor a glória devida ao seu nome; trazei oferendas e entrai nos seus átrios; adorai o
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!
30 Tremei diante dele, todas as terras, pois ele firmou o mundo para que não se abale.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn;
31 Alegrem-se os céus, e a terra exulte; diga-se entre as nações: Reina o
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀;
32 Ruja o mar e a sua plenitude; folgue o campo e tudo o que nele há.
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,
33 Regozijem-se as árvores do bosque na presença do porque vem a julgar a terra.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
34 Rendei graças ao Senhor , porque ele é bom; porque a sua misericórdia dura para sempre.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa;
35 E dizei: Salva-nos, ó Deus da nossa salvação, ajunta-nos e livra-nos das nações, para que rendamos graças ao teu santo nome e nos gloriemos no teu louvor.
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,
36 Bendito seja o Senhor , Deus de Israel, desde a eternidade até a eternidade. E todo o povo disse: Amém! E louvou ao
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
37 Então, Davi deixou ali diante da arca da Aliança do Senhor a Asafe e a seus irmãos, para ministrarem continuamente perante ela, segundo se ordenara para cada dia;
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
38 também deixou a Obede-Edom com seus irmãos, em número de sessenta e oito; a Obede-Edom, filho de Jedutum, e a Hosa, para serem porteiros;
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
39 e deixou a Zadoque, o sacerdote, e aos sacerdotes, seus irmãos, diante do tabernáculo do Senhor , num lugar alto de Gibeão,
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
40 para oferecerem continuamente ao Senhor os holocaustos sobre o altar dos holocaustos, pela manhã e à tarde; e isto segundo tudo o que está escrito na Lei que o Senhor ordenara a Israel.
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
41 E com eles deixou a Hemã, a Jedutum e os mais escolhidos, que foram nominalmente designados para louvarem o Senhor , porque a sua misericórdia dura para sempre.
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
42 Com eles, pois, estavam Hemã e Jedutum, que faziam ressoar trombetas, e címbalos, e instrumentos de música de Deus; os filhos de Jedutum eram porteiros.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
43 Então, se retirou todo o povo, cada um para sua casa; e tornou Davi, para abençoar a sua casa.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.