1 Crônicas 16
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NAA
1 Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, wá sínú àgọ́ ti Dafidi ti pèsè fún un, wọ́n sì gbé ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀ kalẹ̀ níwájú Ọlọ́run.
1 Levaram a arca de Deus e a puseram no meio da tenda que Davi tinha preparado para ela. Então trouxeram holocaustos e ofertas pacíficas diante de Deus.
2 Lẹ́yìn tí Dafidi parí ẹbọ sísun àti ọrẹ ìdàpọ̀, ó bùkún àwọn ènìyàn ní orúkọ Olúwa.
2 Depois de trazer os holocaustos e as ofertas pacíficas, Davi abençoou o povo em nome do Senhor .
3 Nígbà náà ó fún olúkúlùkù ọkùnrin àti obìnrin ọmọ Israẹli ní ìṣù àkàrà kan, àkàrà dídùn ti àkókò kan àti àkàrà dídùn ti èso àjàrà kan.
3 E repartiu a todos em Israel, tanto homens como mulheres, a cada um, um bolo de pão, um bom pedaço de carne e passas.
4 Ó yan díẹ̀ lára àwọn ará Lefi láti máa jọ́sìn níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, àti láti ṣe ìrántí àti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
4 Designou dentre os levitas os que haviam de ministrar diante da arca do Senhor , e celebrar, louvar e exaltar o Senhor , Deus de Israel, a saber,
5 Asafu ni olóyè, àtẹ̀lé rẹ ni Sekariah, Jehieli, Ṣemiramotu, Asieli, Mattitiah, Eliabu, Benaiah, Obedi-Edomu àti Jeieli, àwọn ni yóò lu ohun èlò orin olókùn àti dùùrù haapu. Asafu ni yóò lu símbálì kíkan.
5 Asafe, o chefe, Zacarias, o segundo, e depois Jeiel, Semiramote, Jeiel, Matitias, Eliabe, Benaia, Obede-Edom e Jeiel, com liras e harpas; e Asafe fazia ressoar os címbalos.
6 Àti Benaiah àti Jahasieli àwọn àlùfáà ni yóò fọn ìpè nígbà gbogbo níwájú àpótí ẹ̀rí májẹ̀mú ti Ọlọ́run.
6 Os sacerdotes Benaia e Jaaziel estavam continuamente com trombetas, diante da arca da aliança de Deus.
7 Ní ọjọ́ náà Dafidi kọ́kọ́ fi lé Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ orin Dafidi ti ọpẹ́ sí Olúwa.
7 Foi naquele dia que Davi encarregou, pela primeira vez, Asafe e seus irmãos de celebrarem com hinos o Senhor .
8 Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
8 Deem graças ao Senhor , invoquem o seu nome; tornem conhecidos entre os povos os seus feitos.
9 Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
9 Cantem a Deus, cantem louvores a ele; falem de todas as suas maravilhas.
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
10 Gloriem-se no seu santo nome; alegre-se o coração dos que buscam o
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
11 Busquem o Senhor e o seu poder; busquem continuamente a sua presença.
12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
12 Lembrem-se das maravilhas que ele fez, dos seus prodígios e dos juízos de seus lábios,
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
13 vocês, descendentes de Israel, seu servo, vocês, filhos de Jacó, seus escolhidos.
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
14 Ele é o Senhor , nosso Deus; os seus juízos permeiam toda a terra.
15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
15 Lembra-se perpetuamente da sua aliança, da palavra que empenhou para mil gerações;
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
16 da aliança que fez com Abraão e do juramento que fez a Isaque;
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
17 o qual confirmou a Jacó por decreto e a Israel, por aliança perpétua,
18 “Sí ọ, ni èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
18 dizendo: “Eu lhe darei a terra de Canaã como porção da sua herança.”
19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
19 Então eles eram em pequeno número, pouquíssimos e estrangeiros na terra de Canaã;
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
20 andavam de nação em nação, de um reino para outro reino.
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
21 Deus não permitiu que ninguém os oprimisse, e, por amor deles, repreendeu reis,
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni àmì òróró mi;
22 dizendo: “Não toquem nos meus ungidos, nem maltratem os meus profetas.”
23 Kọrin sí Olúwa gbogbo ayé;
23 Cantem ao Senhor , todas as terras; proclamem a sua salvação, dia após dia.
24 Kéde ògo à rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
24 Anunciem entre as nações a sua glória, entre todos os povos, as suas maravilhas.
25 Nítorí títóbi ni Olúwa òun sì ni ìyìn yẹ jùlọ;
25 Porque o Senhor é grande e digno de ser louvado, mais temível do que todos os deuses.
26 Nítorí gbogbo àwọn ọlọ́run orílẹ̀-èdè jẹ́ àwọn òrìṣà,
26 Porque todos os deuses dos povos não passam de ídolos; o
27 Dídán àti ọláńlá ni ó wà níwájú rẹ̀;
27 Glória e majestade estão diante dele, força e alegria, no seu santuário.
28 Fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè,
28 Deem ao Senhor , ó famílias dos povos, deem ao
29 Fún Olúwa ní ìyìn nítorí orúkọ rẹ̀;
29 Deem ao Senhor a glória devida ao seu nome; tragam ofertas e entrem nos seus átrios. Adorem o na beleza da sua santidade.
30 Wárìrì níwájú rẹ̀, gbogbo ayé!
30 Tremam diante dele, todas as terras, pois ele firmou o mundo para que não se abale.
31 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, jẹ́ kí ayé kí ó ṣe inú dídùn;
31 Alegrem-se os céus, e a terra exulte; diga-se entre as nações: “O
32 Jẹ́ kí ọ̀run kí ó tún dún padà, àti gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀;
32 Ruja o mar e a sua plenitude; alegre-se o campo e tudo o que nele há.
33 Nígbà náà ni igi igbó yóò kọrin,
33 Cantem de alegria as árvores do bosque, na presença do porque vem julgar a terra.
34 Fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
34 Deem graças ao Senhor , porque ele é bom, porque a sua misericórdia dura para sempre.
35 Ké lóhùn rara, “Gbà wá, Ọlọ́run olùgbàlà a wa;
35 E digam: “Salva-nos, ó Deus da nossa salvação, congrega-nos e livra-nos das nações, para que demos graças ao teu santo nome e nos gloriemos no teu louvor.”
36 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli,
36 Bendito seja o Senhor , Deus de Israel, de eternidade a eternidade. E todo o povo disse: “Amém!” E louvou o
37 Dafidi fi Asafu àti àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ sílẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa láti jíṣẹ́ níbẹ̀ déédé, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ kọ̀ọ̀kan ṣe gbà.
37 Então Davi deixou Asafe e seus irmãos ali diante da arca da aliança do Senhor , para ministrarem continuamente diante dela, segundo o que estava ordenado para cada dia.
38 Ó fi Obedi-Edomu àti méjìdínláàádọ́rin ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú wọn. Obedi-Edomu mọ Jedutuni, àti Hosa pẹ̀lú jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
38 Também deixou Obede-Edom com os seus irmãos, em número de sessenta e oito, bem como Obede-Edom, filho de Jedutum, e Hosa, para serem porteiros.
39 Dafidi fi Sadoku àlùfáà àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ níwájú Àgọ́ Olúwa ní ibi gíga ní Gibeoni.
39 E deixou Zadoque, o sacerdote, e os sacerdotes, seus irmãos, diante do tabernáculo do Senhor , num lugar alto de Gibeão,
40 Láti gbé pẹpẹ ẹbọ sísun déédé, àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú òfin Olúwa, tí ó ti fún Israẹli.
40 para oferecerem continuamente ao Senhor os holocaustos sobre o altar dos holocaustos, de manhã e de tarde, segundo tudo o que está escrito na Lei que o Senhor havia ordenado a Israel.
41 Pẹ̀lú wọn ni Hemani àti Jedutuni àti ìyókù tí a mú àti yàn nípasẹ̀ orúkọ láti fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé
41 E com eles deixou Hemã, Jedutum e os demais escolhidos, que foram nominalmente designados para louvarem o Senhor , porque a sua misericórdia dura para sempre.
42 Hemani àti Jedutuni ni wọ́n dúró fún fífọn ìpè àti Kimbali àti fún lílo ohun èlò yòókù fún orin Ọlọ́run. Àwọn ọmọ Jedutuni wà ní ipò dídúró ní ẹnu-ọ̀nà.
42 Portanto, com eles estavam Hemã e Jedutum, que faziam ressoar trombetas, címbalos e instrumentos musicais usados para louvar a Deus. Os filhos de Jedutum eram porteiros.
43 Nígbà náà gbogbo àwọn ènìyàn kúrò, olúkúlùkù sí ilé rẹ̀: Dafidi yípadà láti súre fún ìdílé rẹ̀.
43 Então todo o povo se retirou, cada um para sua casa; Davi também foi, para abençoar a sua casa.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.