1 Crônicas 8
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs VC
1 Benjamini jẹ́ baba:
1 Benjamim gerou Bela, seu primogênito, Asbel, o segundo, Aara, o terceiro,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
2 Noaa, o quarto e Rafa, o quinto.
3 Àwọn ọmọ Bela ni,
3 Filhos de Bela: Adar, Gera, Abiud, Abisué, Naamã, Aoé,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
4 Gera, Sefufã,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
5 Hurão.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
6 Filhos de Aod: eram os chefes das famílias que habitavam Gabaa, transportados para Manaat:
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
7 Naamã, Aquia e Gera, que os transportou, o qual gerou Oza e Aiud.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
8 Saarain teve filhos na terra de Moab, depois de ter repudiado suas mulheres Husim e Bara.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
9 Nasceram de Hodes, sua mulher: Jobab, Sebia, Mosa, Molcon, Jeús, Sequia e Marma,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
10 que são seus filhos, chefes de famílias.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
11 De Husin teve Abitob e Elfaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali:
12 Filhos de Elfaal: Heber, Misaão e Samad, que construiu Ono e Lod, e as cidades que dela dependem.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
13 Baria e Sama, chefes das famílias que habitavam Aialon, puseram em fuga os habitantes de Get.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
14 Aio, Sesac, Jerimot,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
15 Zabadia, Arod, Heder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
16 Miguel, Jesfa e Joá eram filhos de Baria.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
17 Zabadia, Mosolão, Hezeci, Heber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
18 Jesamari, Jezlia e Jobab eram filhos de Elfaal.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
19 Jacim, Zecri, Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
20 Elioenai, Seletai, Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
21 Adaia, Baraia e Samarat eram filhos de Semei.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
22 Jesfã, Heber, Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
23 Abdon, Zecri, Hanã,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
24 Hanania, Elão, Anatotia,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
25 Jefdaia e Fanuel eram filhos de Sesac.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
26 Samsari, Sooria, Otolia,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
27 Jersia, Elia e Zecri eram filhos de Jeroão.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
28 São estes os chefes de famílias, chefes segundo suas genealogias. Habitavam em Jerusalém.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
29 O pai de Gabaon morava em Gabaon; sua mulher chamava-se Maaca.
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
30 Seu filho mais velho: Abdon; em seguida, Sur, Cis, Baal, Nadab,
31 Gedori Ahio, Sekeri
31 Gedor, Aio e Zaquer.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
32 Macelot gerou Samaa. Eles habitavam também Jerusalém com seus irmãos.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
33 Ner gerou Cis, Cis gerou Saul, Saul gerou Jônatas, Melquisua, Abinadab e Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani:
34 Filho de Jônatas: Meribaal. Meribaal gerou Mica.
35 Àwọn ọmọ Mika:
35 Filhos de Mica: Fiton, Melec, Taraa e Acaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
36 Acaz gerou Joada, Joada gerou Alamot, Azmot e Zamri. Zamri gerou Mosa.
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
37 Mosa gerou Banaa, Rafa, seu filho, Elasa, seu filho, Asel, seu filho.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
38 Asel teve seis filhos, cujos nomes são: Esricão, Bocru, Ismael, Saria, Obdias e Hanã, todos filhos de Asel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki:
39 Filhos de Esec, seu irmão: Ulão, seu filho mais velho, Jeús, o segundo, e Elifalet, o terceiro.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀.
40 Os filhos de Ulão eram homens valentes, bons arqueiros; tiveram numerosos filhos e netos: cento e cinqüenta. Todos esses são descendentes de Benjamim.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.