1 Crônicas 8

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARIB

Sair da comparação
ARIB Almeida Revisada Imprensa Bíblica
1 Benjamini jẹ́ baba:
1 Benjamim foi pai de Belá, seu primogênito, de Asbel o segundo, e de Aará o terceiro,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
2 de Noá o quarto, e de Rafa o quinto.
3 Àwọn ọmọ Bela ni,
3 Belá teve estes filhos: Adar, Gêra, Abiúde,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
4 Abisua, Naamã, Aoá,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
5 Gêra, Sefufã e Hurão.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
6 Estes foram os filhos de Eúde, que foram os chefes das casas paternas dos habitantes de Geba, e que foram levados cativos para Manaate;
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
7 Naamã, Aías e Gêra; este os transportou; foi ele pai de Uzá e Aiúde.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
8 Saaraim teve filhos na terra de Moabe, depois que despedira Husim e Baara, suas mulheres.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
9 E de Hodes, sua mulher, teve Jobabe, Zíbia, Messa, Malcã,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
10 Jeuz, Saquias e Mirma; esses foram seus filhos:, chefes de casas paternas:
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
11 De Husim teve Abitube e Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali:
12 Os filhos de Elpaal: Eber, Misã, Semede {este edificou Ono e Lode e suas aldeias},
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
13 Berias e Sema {estes foram chefes de casas paternas dos habitantes de Aijalom, os quais afugentaram os habitantes de Gatel ,
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
14 Aiô, Sasaque e Jerimote.
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
15 Zebadias, Arade, Eder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
16 Micael, Ispá e Joá foram filhos de Berias;
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
17 Zebadias, Mesulão, Hizqui, Heber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
18 Ismerai, Izlias e Jobabe foram filhos de Elpaal;
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
19 Jaquim, Zicri, Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
20 Elienai, Ziletai, Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
21 Adaías, Beraías e Sinrate foram filhos de Simei;
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
22 Ispã, Eber, Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
23 Abdom, Zicri, Hanã,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
24 Hananias, Elão, Antotias,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
25 Ifdéias e Penuel foram filhos de Sasaque;
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
26 Sanserai, Searias, Atalias,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
27 Jaaresias, Elias e Zicri foram filhos de Jeroão.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
28 Estes foram chefes de casas paternas, segundo as suas gerações, homens principais; e habitaram em Jerusalém.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
29 E em Gibeão habitaram o pai de Gibeão, cuja mulher se chamava Maacá,
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
30 e seu filho primogênito Abdom, depois Zur, Quiz, Baal, Nadabe,
31 Gedori Ahio, Sekeri
31 Gedor, Aiô, Zequer e Miclote.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
32 Miclote foi pai de Siméia; também estes habitaram em Jerusalém defronte de seus irmãos.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
33 Ner foi pai de Quis, e Quis de Saul; Saul foi pai de Jônatas, Malquisua, Abinadabe e Es-Baal.
34 Ọmọ Jonatani:
34 Filho de Jônatas foi Meribe-Baal; e Meribe-Baal foi pai de Mica.
35 Àwọn ọmọ Mika:
35 Os filhos de Mica foram: Pitom, Meleque, Tareá e Acaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
36 Acaz foi pai de Jeoada; Jeoada foi pai de Alemete, Azmavete e Zinri; Zinri foi pai de Moza;
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
37 Moza foi pai de Bineá, de quem foi filho Rafa, de quem foi filho Eleasá, de quem foi filho Azel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
38 Azel teve seis filhos, cujos nomes foram: Azricão, Bocru, Ismael, Searias, Obadias e Hanã; todos estes foram filhos de Azel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki:
39 Os filhos de Eseque, seu irmão: Ulão, seu primogênito, Jeús o segundo, e Elifelete o terceiro.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀.
40 Os filhos de Ulão foram homens heróis, valentes, e flecheiros destros; e tiveram muitos filhos, e filhos de filhos, cento e cinqüenta. Todos estes foram dos filhos de Benjamim.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.