1 Crônicas 8
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Benjamini jẹ́ baba:
1 Ora, Benjamim gerou Belá, o seu primogênito; Asbel, o segundo; e Aará, o terceiro;
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
2 Noá, o quarto; e Rafa, o quinto.
3 Àwọn ọmọ Bela ni,
3 E os filhos de Belá foram: Adar, e Gera, e Abiúde,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
4 e Abisua, e Naamã, e Aoá,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
5 e Gera, e Sefufã, e Hurão.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
6 E estes são os filhos de Eúde: Estes são os cabeças dos pais dos habitantes de Geba, e os que foram levados para Manaate;
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
7 e Naamã, e Aías, e Gera, ele os levou, e gerou Uzá, e Ailude.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
8 E Saaraim gerou filhos na terra de Moabe, depois de ter repudiado suas mulheres Husim e Baara.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
9 E ele gerou, de Hodes, sua esposa: Jobabe e Zíbia, e Messa, e Malcã,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
10 e Jeús, e Saquias, e Mirma. Estes foram os seus filhos, cabeças dos pais.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
11 E de Husim, ele gerou Abitube, e Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali:
12 Os filhos de Elpaal: Héber, e Misã, e Semede; que edificou Ono, e Lode, com as suas aldeias;
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
13 também Berias, e Sema, que foram cabeças dos pais dos habitantes de Aijalom, que expeliu os habitantes de Gate;
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
14 e Aiô, Sasaque e Jerimote,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
15 e Zebadias, e Arade, e Éder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
16 e Micael, e Ispa, e Joá, os filhos de Berias;
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
17 e Zebadias, e Mesulão, e Hizqui, e Héber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
18 E Ismerai, e Izlias, e Jobabe, os filhos de Elpaal;
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
19 E Jaquim, e Zicri, e Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
20 e Elienai, e Ziletai, e Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
21 e Adaías, e Beraías, e Sinrate, os filhos de Simei;
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
22 e Ispã, e Héber, e Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
23 e Abdom, e Zicri, e Hanã,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
24 e Hananias, e Elão, e Antotias,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
25 e Ifdeias, e Penuel, os filhos de Sasaque;
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
26 e Sanserai, e Searias, e Atalias,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
27 e Jaaresias, e Elias, e Zicri, filhos de Jeroão.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
28 Estes foram os cabeças dos pais, pelas suas gerações, chefes. Estes habitaram em Jerusalém.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
29 E, em Gibeão, habitou o pai de Gibeão; cuja esposa tinha o nome de Maaca,
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
30 e o seu filho primogênito Abdom, e Zur, e Quis, e Baal, e Nadabe,
31 Gedori Ahio, Sekeri
31 e Gedor, e Aiô, e Zequer.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
32 E Miclote gerou Simeia. Estes também habitaram em Jerusalém com seus irmãos, diante deles.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
33 E Ner gerou Quis, e Quis gerou Saul; e Saul gerou Jônatas, e Malquisua, e Abinadabe, e Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani:
34 E o filho de Jônatas foi Meribe-Baal; e Meribe-Baal gerou Mica.
35 Àwọn ọmọ Mika:
35 E os filhos de Mica foram: Pitom, e Meleque e Tareia, e Acaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
36 E Acaz gerou Jeoada, e Jeoada gerou Alemete, e Azmavete, e Zinri; e Zinri gerou Mosa,
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
37 e Mosa gerou Bineá; Rafa foi o seu filho, Eleasa, seu filho; Azel, seu filho.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
38 E Azel teve seis filhos, cujos nomes são estes: Azricão, Bocru, e Ismael, e Searias, e Obadias, e Hanã. Todos estes foram os filhos de Azel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki:
39 E os filhos de Eseque, o seu irmão, foram: Ulão, o seu primogênito; Jeús, o segundo; e Elifelete, o terceiro.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀.
40 E os filhos de Ulão foram homens fortes e valentes, arqueiros, e tiveram muitos filhos, e filhos de filhos; cento e cinquenta. Todos estes são os filhos de Benjamim.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.