1 Crônicas 8
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NVT
1 Benjamini jẹ́ baba:
1 O primeiro filho de Benjamim foi Belá, o segundo, Asbel, o terceiro, Aará,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
2 o quarto, Noá, e o quinto, Rafa.
3 Àwọn ọmọ Bela ni,
3 Os filhos de Belá foram: Adar, Gera, Abiúde,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
4 Abisua, Naamã, Aoá,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
5 Gera, Sefufá e Hurão.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
6 Os filhos de Eúde, chefes dos clãs que habitavam em Geba, foram deportados para Maanate.
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
7 Os filhos de Eúde foram: Naamã, Aías e Gera. Gera, que os exilou, foi o pai de Uzá e Aiúde.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
8 Depois que Saarim se divorciou de suas esposas Husim e Baara, teve filhos na terra de Moabe.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
9 Hodes, sua esposa, deu à luz Jobabe, Zíbia, Messa, Malcã,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
10 Jeús, Saquias e Mirma. Todos esses filhos foram chefes de clãs.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
11 Husim, esposa de Saarim, deu à luz Abitube e Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali:
12 Os filhos de Elpaal foram Héber, Misã, Semede (que construiu as cidades de Ono e Lode, com seus povoados),
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
13 Berias e Sema. Todos eles foram chefes de clãs que habitavam em Aijalom; eles expulsaram os moradores de Gate.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
14 Aiô, Sasaque, Jeremote,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
15 Zebadias, Arade, Éder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
16 Micael, Ispa e Joá foram os filhos de Berias.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
17 Zebadias, Mesulão, Hizqui, Héber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
18 Ismerai, Izlias e Jobabe foram filhos de Elpaal.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
19 Jaquim, Zicri, Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
20 Elienai, Ziletai, Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
21 Adaías, Beraías e Sinrate foram filhos de Simei.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
22 Ispã, Héber, Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
23 Abdom, Zicri, Hanã,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
24 Hananias, Elão, Antotias,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
25 Ifdeias e Penuel foram filhos de Sasaque.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
26 Sanserai, Searias, Atalias,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
27 Jaaresias, Elias e Zicri foram filhos de Jeroão.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
28 Esses foram os chefes dos clãs, conforme listados em seus registros genealógicos; todos moravam em Jerusalém.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
29 Jeiel, pai de Gibeom, morava em Gibeom. Sua esposa se chamava Maaca,
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
30 e seu filho mais velho, Abdom. Os outros filhos de Jeiel foram: Zur, Quis, Baal, Ner, Nadabe,
31 Gedori Ahio, Sekeri
31 Gedor, Aiô, Zacarias
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
32 e Miclote, que gerou Simeão. Todos moravam com suas famílias, próximos uns dos outros, em Jerusalém.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
33 Ner gerou Quis. Quis gerou Saul. Os filhos de Saul foram: Jônatas, Malquisua, Abinadabe e Isbosete.
34 Ọmọ Jonatani:
34 O filho de Jônatas se chamava Mefibosete. Mefibosete gerou Mica.
35 Àwọn ọmọ Mika:
35 Os filhos de Mica foram: Pitom, Meleque, Tareia e Acaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
36 Acaz gerou Jadá. Os filhos de Jadá foram: Alemete, Azmavete e Zinri. Zinri gerou Moza.
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
37 Moza gerou Bineá. Bineá gerou Refaías. Refaías gerou Eleasá. Eleasá gerou Azel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
38 Azel teve seis filhos: Azricão, Bocru, Ismael, Searias, Obadias e Hanã. Todos esses foram filhos de Azel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki:
39 Eseque, irmão de Azel, teve três filhos: o primeiro se chamava Ulão, o segundo, Jeús, e o terceiro, Elifelete.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀.
40 Todos os filhos de Ulão foram guerreiros valentes e arqueiros habilidosos. Tiveram muitos filhos e netos, 150 ao todo. Todos esses foram descendentes de Benjamim.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.