1 Crônicas 8

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARA

Sair da comparação
ARA Almeida Revista e Atualizada 1993
1 Benjamini jẹ́ baba:
1 Benjamim gerou a Bela, seu primogênito, a Asbel, o segundo, a Aará, o terceiro,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
2 a Noá, o quarto, e a Rafa, o quinto.
3 Àwọn ọmọ Bela ni,
3 Bela teve estes filhos: Adar, Gera, Abiúde,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
4 Abisua, Naamã, Aoá,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
5 Gera, Sefufá e Hurão.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
6 Estes foram os filhos de Eúde, que foram chefes das famílias dos moradores de Geba e transportados para o exílio a Manaate:
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
7 Naamã, Aías e Gera; este os transportou e gerou a Uzá e a Aiude.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
8 Saaraim, depois de ter repudiado suas mulheres Husim e Baara, gerou nos campos de Moabe,
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
9 de Hodes, sua mulher, a Jobabe, a Zíbia, a Messa, a Malcã,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
10 a Jeús, a Saquias e a Mirma; foram estes os seus filhos, chefes das famílias.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
11 Husim gerou a Abitube e a Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali:
12 Os filhos de Elpaal foram: Héber, Misã e Semede; este edificou a Ono e a Lode e suas aldeias.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
13 Berias e Sema foram cabeças das famílias dos moradores de Aijalom, que afugentaram os moradores de Gate.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
14 Aiô, Sasaque, Jeremote,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
15 Zebadias, Arade, Éder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
16 Micael, Ispa e Joá foram filhos de Berias.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
17 Zebadias, Mesulão, Hizqui, Héber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
18 Ismerai, Izlias e Jobabe, filhos de Elpaal.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
19 Jaquim, Zicri, Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
20 Elienai, Ziletai, Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
21 Adaías, Beraías e Sinrate, filhos de Simei.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
22 Ispã, Héber, Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
23 Abdom, Zicri, Hanã,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
24 Hananias, Elão, Antotias,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
25 Ifdeias e Penuel, filhos de Sasaque.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
26 Sanserai, Searias, Atalias,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
27 Jaaresias, Elias e Zicri, filhos de Jeroão.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
28 Estes foram chefes das famílias, segundo as suas gerações, e habitaram em Jerusalém.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
29 Em Gibeão habitou o pai de Gibeão, cuja mulher se chamava Maaca,
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
30 e também seu filho primogênito Abdom e ainda Zur, Quis, Baal, Nadabe,
31 Gedori Ahio, Sekeri
31 Gedor, Aiô e Zequer.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
32 Miclote gerou a Simeia. Estes habitaram em Jerusalém, com seus irmãos, bem defronte deles.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
33 Ner gerou a Quis; e Quis gerou a Saul; Saul gerou a Jônatas, a Malquisua, a Abinadabe e a Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani:
34 Filho de Jônatas foi Meribe-Baal, e Meribe-Baal gerou a Mica.
35 Àwọn ọmọ Mika:
35 Os filhos de Mica foram: Pitom, Meleque, Tareia e Acaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
36 Acaz gerou a Jeoada; Jeoada gerou a Alemete, a Azmavete e a Zinri; e Zinri gerou a Mosa.
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
37 Mosa gerou a Bineá, de quem foi filho Rafa, de quem foi filho Eleasa, de quem foi filho Azel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
38 Teve Azel seis filhos, cujos nomes foram: Azricão, Bocru, Ismael, Searias, Obadias e Hanã; todos estes foram filhos de Azel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki:
39 Os filhos de Eseque, seu irmão, foram: Ulão, seu primogênito, Jeús, o segundo, e Elifelete, o terceiro.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀.
40 Os filhos de Ulão foram homens valentes, flecheiros; e tiveram muitos filhos e netos: cento e cinquenta. Todos estes foram dos filhos de Benjamim.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.