1 Crônicas 8
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NVI
1 Benjamini jẹ́ baba:
1 Benjamim gerou Belá, seu filho mais velho; Asbel, seu segundo filho, Aará, o terceiro,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
2 Noá, o quarto, e Rafa, o quinto.
3 Àwọn ọmọ Bela ni,
3 Estes foram os filhos de Belá: Adar, Gera, pai de Eúde,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
4 Abisua, Naamã, Aoá,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
5 Gera, Sefufá e Hurão.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
6 Estes foram os descendentes de Eúde, chefes das famílias dos habitantes de Geba, que foram deportados para Manaate:
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
7 Naamã, Aías e Gera. Esse Gera, pai de Uzá e de Aiúde, foi quem os deportou.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
8 Depois de ter se divorciado de suas mulheres Husim e Baara, Saaraim teve filhos na terra de Moabe.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
9 Com sua mulher Hodes ele gerou Jobabe, Zíbia, Messa, Malcã,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
10 Jeús, Saquias e Mirma. Esses foram seus filhos, chefes de famílias.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
11 Com Husim ele gerou Abitube e Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali:
12 Estes foram os filhos de Elpaal: Héber, Misã, Semede, que fundou Ono e Lode com seus povoados.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
13 Berias e Sema foram os chefes das famílias dos habitantes de Aijalom, e foram eles que expulsaram os habitantes de Gate.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
14 Aiô, Sasaque, Jeremote,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
15 Zebadias, Arade, Éder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
16 Micael, Ispa e Joá foram descendentes de Berias.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
17 Zebadias, Mesulão, Hizqui, Héber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
18 Ismerai, Izlias e Jobabe foram descendentes de Elpaal.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
19 Jaquim, Zicri, Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
20 Elienai, Ziletai, Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
21 Adaías, Beraías e Sinrate foram descendentes de Simei.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
22 Ispã, Héber, Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
23 Abdom, Zicri, Hanã,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
24 Hananias, Elão, Antotias,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
25 Ifdéias e Penuel foram descendentes de Sasaque.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
26 Sanserai, Searias, Atalias,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
27 Jaaresias, Elias e Zicri foram descendentes de Jeroão.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
28 Todos esses foram chefes de famílias, líderes conforme alistados em suas genealogias, e moravam em Jerusalém.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
29 Jeiel, pai de Gibeom morou na cidade de Gibeom. O nome de sua mulher era Maaca,
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
30 o de seu filho mais velho, Abdom, e o de seus outros filhos, Zur, Quis, Baal, Ner, Nadabe,
31 Gedori Ahio, Sekeri
31 Gedor, Aiô, Zequer
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
32 e Miclote, que gerou Siméia. Eles também moravam perto de seus parentes, em Jerusalém.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
33 Ner gerou Quis, que gerou Saul. Saul gerou Jônatas, Malquisua, Abinadabe e Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani:
34 O filho de Jônatas foi Meribe-Baal, que gerou Mica.
35 Àwọn ọmọ Mika:
35 Estes foram os filhos de Mica: Pitom, Meleque, Taréia e Acaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
36 Acaz gerou Jeoada, Jeoada gerou Alemete, Azmavete e Zinri, e Zinri gerou Mosa.
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
37 Mosa gerou Bineá, pai de Rafa, que foi o pai de Eleasa, pai de Azel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
38 Azel teve seis filhos chamados Azricão, Bocru, Ismael, Searias, Obadias e Hanã. Todos esses foram filhos de Azel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki:
39 Estes foram os filhos de Eseque, seu irmão: Ulão, o mais velho, Jeús, o segundo e Elifelete, o terceiro.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀.
40 Os filhos de Ulão eram soldados valentes e bons flecheiros. Tiveram muitos filhos e netos; eram cento e cinqüenta ao todo. Todos esses foram descendentes de Benjamim.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.