1 Crônicas 8

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ACF

Sair da comparação
ACF Almeida Corrigida Fiel
1 Benjamini jẹ́ baba:
1 E Benjamim gerou a Belá, seu primogênito, a Asbel o segundo, e a Aará o terceiro,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
2 A Noá o quarto, e a Rafa o quinto.
3 Àwọn ọmọ Bela ni,
3 E Belá teve estes filhos: Adar, Gera, Abiúde,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
4 Abisua, Naamã, Aoá,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
5 Gera, Sefufá e Hurão.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
6 E estes foram os filhos de Eúde; que foram chefes dos pais dos moradores de Geba, e os levaram cativos a Manaate;
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
7 E Naamã, e Aías e Gera; este os transportou, e gerou a Uzá e a Aiúde.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
8 E Saaraim (depois de os enviar), na terra de Moabe, gerou filhos de Husim e Baara, suas mulheres.
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
9 E de Hodes, sua mulher, gerou a Jobabe, a Zíbia, a Mesa, a Malcã,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
10 A Jeuz, a Saquias e a Mirma; estes foram seus filhos, chefes dos pais.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
11 E de Husim gerou a Abitube e a Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali:
12 E foram os filhos de Elpaal: Éber, Misã e Semede; este edificou a Ono e a Lode e os lugares da sua jurisdição.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
13 E Berias e Sema foram cabeças dos pais dos moradores de Aijalom; estes afugentaram os moradores de Gate.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
14 E Aiô, Sasaque, Jerimote,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
15 Zebadias, Arade, Eder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
16 Micael, Ispa e Joa foram filhos de Berias.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
17 Zebadias, Mesulão, Hizque, Héber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
18 Ismerai, Izlias e Jobabe, filhos de Elpaal.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
19 Jaquim, Zicri, Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
20 Elienai, Ziletai, Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
21 Adaías, Beraías e Sinrate, filhos de Simei.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
22 E Ispã, Éber, Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
23 Abdom, Zicri, Hanã,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
24 Hananias, Elão, Antotias,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
25 E Ifdéias, e Penuel, filhos de Sasaque;
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
26 E Sanserai, e Searias, e Atalias,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
27 E Jaaresias, e Elias e Zicri, filhos de Jeroão.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
28 Estes foram cabeças dos pais, segundo as suas gerações, chefes, e habitaram em Jerusalém.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
29 E em Gibeão habitou o pai de Gibeão; e era o nome de sua mulher Maaca;
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
30 E seu filho primogênito, Abdom; depois Zur, e Quis, Baal, e Nadabe,
31 Gedori Ahio, Sekeri
31 E Gedor, Aiô, e Zequer,
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
32 E Miclote gerou a Siméia; e também estes, defronte de seus irmãos, habitaram em Jerusalém com eles.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
33 E Ner gerou a Quis, e Quis gerou a Saul; e Saul gerou a Jônatas, a Malquisua, a Abinadabe, e a Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani:
34 E o filho de Jônatas foi Meribe-Baal; e Meribe-Baal gerou a Mica.
35 Àwọn ọmọ Mika:
35 E os filhos de Mica foram: Pitom, Meleque, Tareá, e Acaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
36 E Acaz gerou a Jeoada; e Jeoada gerou a Alemete, e a Azmavete, e a Zinri; e Zinri gerou a Moza,
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
37 E Moza gerou a Bineá, cujo filho foi Rafa, de quem foi filho Eleasá, cujo filho foi Azel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
38 E teve Azel seis filhos, e estes foram os seus nomes: Azricão, Bocru, Ismael, Searias, Obadias, e Hanã; todos estes foram filhos de Azel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki:
39 E os filhos de Ezeque, seu irmão: Ulão, seu primogênito, Jeús o segundo e Elifelete o terceiro.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀.
40 E foram os filhos de Ulão homens heróis, valentes, e flecheiros destros; e tiveram muitos filhos, e filhos de filhos, cento e cinqüenta; todos estes foram dos filhos de Benjamim.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.