1 Crônicas 8

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARC

Sair da comparação
ARC Almeida Revista e Corrigida 2009
1 Benjamini jẹ́ baba:
1 E Benjamim gerou a Belá, seu primogênito, a Asbel, o segundo e a Aará, o terceiro,
2 Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
2 e a Noá, o quarto, e a Rafa, o quinto,
3 Àwọn ọmọ Bela ni,
3 e Belá teve estes filhos: Adar, e Gera, e Abiúde,
4 Abiṣua, Naamani, Ahoa,
4 e Abisua, e Naamã, e Aoá,
5 Gera, Ṣefufani àti Huramu.
5 e Gera, e Sefufã, e Hurão.
6 Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
6 E estes foram os filhos de Eúde, que foram chefes dos pais dos moradores de Geba, e os transportados a Manaate:
7 Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
7 Naamã, e Aías, e Gera; a estes Gera transportou e gerou a Uzá e a Aiude.
8 A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
8 E Saaraim (depois de ter repudiado suas mulheres Husim e Baara), na terra de Moabe, gerou filhos,
9 Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
9 e de Hodes, sua mulher, gerou a Jobabe, e a Zíbia, e a Messa, e a Malcã,
10 Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
10 e a Jeús, e a Saquias, e a Mirma; estes foram seus filhos, chefes dos pais.
11 Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
11 E de Husim gerou a Abitube e a Elpaal.
12 Àwọn ọmọ Elipali:
12 E foram os filhos de Elpaal: Héber, e Misã, e Semede; este edificou a Ono, e a Lode, e os lugares da sua jurisdição.
13 Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
13 E Berias e Sema foram cabeças dos pais dos moradores de Aijalom; estes afugentaram os moradores de Gate.
14 Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
14 E Aiô, e Sasaque, e Jeremote,
15 Sebadiah, Aradi, Ederi
15 e Zebadias, e Arade, e Éder,
16 Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
16 e Micael, e Ispa, e Joá foram filhos de Berias.
17 Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
17 E Zebadias, e Mesulão, e Hizqui, e Héber,
18 Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
18 e Ismerai, e Izlias, e Jobabe, filhos de Elpaal.
19 Jakimu, Sikri, Sabdi,
19 E Jaquim, e Zicri, e Zabdi,
20 Elienai, Siletai, Elieli,
20 e Elienai, e Ziletai, e Eliel,
21 Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
21 e Adaías e Beraías, e Sinrate, filhos de Simei.
22 Iṣipani Eberi, Elieli,
22 E Ispã, e Éber, e Eliel,
23 Abdoni, Sikri, Hanani,
23 e Abdom, e Zicri, e Hanã,
24 Hananiah, Elamu, Anitotijah,
24 e Hananias, e Elão, e Antotias,
25 Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
25 e Ifdeias, e Penuel, filhos de Sasaque.
26 Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
26 E Sanserai, e Searias, e Atalias,
27 Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
27 e Jaaresias, e Elias, e Zicri, filhos de Jeroão.
28 Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
28 Estes foram chefes dos pais, segundo as suas gerações, e habitaram em Jerusalém.
29 Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni.
29 E em Gibeão habitou o pai de Gibeão; e era o nome de sua mulher Maaca,
30 àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
30 e seu filho primogênito Abdom, depois Zur, e Quis, e Baal, e Nadabe,
31 Gedori Ahio, Sekeri
31 e Gedor, e Aiô, e Zequer.
32 pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
32 E Miclote gerou a Simeia, e também estes, defronte de seus irmãos, habitaram em Jerusalém com seus irmãos.
33 Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
33 E Ner gerou a Quis, e Quis gerou a Saul; e Saul gerou a Jônatas, e a Malquisua, e a Abinadabe, e a Esbaal.
34 Ọmọ Jonatani:
34 E filho de Jônatas foi Meribe-Baal; e Meribe-Baal gerou a Mica.
35 Àwọn ọmọ Mika:
35 E os filhos de Mica foram: Pitom, e Meleque, e Tareia, e Acaz.
36 Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
36 E Acaz gerou a Jeoada, e Jeoada gerou a Alemete, e a Azmavete, e a Zinri; e Zinri gerou a Mosa,
37 Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
37 e Mosa gerou a Bineá, cujo filho foi Rafa, cujo filho foi Eleasa, cujo filho foi Azel.
38 Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn:
38 E teve Azel seis filhos, e estes foram os seus nomes: Azricão, e Bocru, e Ismael, e Searias, e Obadias, e Hanã; todos estes foram filhos de Azel.
39 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki:
39 E os filhos de Eseque, seu irmão: Ulão, seu primogênito, Jeús, o segundo, e Elifelete, o terceiro.
40 Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀.
40 E foram os filhos de Ulão varões heróis, valentes, e flecheiros destros; e tiveram muitos filhos, e filhos de filhos, cento e cinquenta; todos estes foram dos filhos de Benjamim.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.