1 Crônicas 24

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs VC

Sair da comparação
VC Versão Católica
1 Àwọn wọ̀nyí sì ni pínpín àwọn ọmọ Aaroni.
1 Eis as classes dos filhos de Aarão: Nadab, Abiú, Eleazar e Itamar.
2 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú kí ó tó di wí pé baba wọn kú, wọn kò sì ní àwọn ọmọ; bẹ́ẹ̀ ni Eleasari àti Itamari sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àlùfáà.
2 Nadab e Abiú morreram antes de seu pai, sem filhos, e Eleazar e Itamar exerceram as funções do sacerdócio.
3 Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Sadoku ọmọ Eleasari àti Ahimeleki ọmọ Itamari, Dafidi sì yà wọ́n nípa nínú ìpín fún ìyàsọ́tọ̀ àwọn iṣẹ́ ìsìn wọn.
3 Davi, Sadoc, da linhagem de Eleazar, e Aquimelec, da linhagem de Itamar, dividiram os filhos de Aarão por classes, segundo o serviço deles.
4 A rí ọ̀pọ̀ àwọn olórí lára àwọn ọmọ Eleasari ju lára àwọn ọmọ Itamari lọ, wọ́n sì pín wọn lẹ́sẹ lẹ́sẹ: mẹ́rìndínlógún olórí láti ìdílé ọmọ Eleasari ìran wọn àti olórí méjọ ìdílé láti ara àwọn ọmọ Itamari.
4 Havia entre os filhos de Eleazar mais chefes que entre os filhos de Itamar; foram assim distribuídos: para os filhos de Eleazar, dezesseis chefes de família, e, para os filhos de Itamar, oito chefes de família.
5 Wọ́n sì pín wọn láìṣègbè nípa yíya ìpín, nítorí àwọn olórí ibi mímọ́ àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run wà láàrín àwọn ọmọ méjèèjì Eleasari àti Itamari.
5 Uns e outros foram divididos pela sorte, porque havia príncipes do santuário e príncipes de Deus, tanto entre os filhos de Eleazar, como entre os filhos de Itamar.
6 Ṣemaiah ọmọ Netaneli, akọ̀wé ọ̀kan lára àwọn ọmọ Lefi sì kọ orúkọ wọn níwájú ọba àti àwọn ìjòyè: Sadoku àlùfáà, Ahimeleki ọmọ Abiatari àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà tí a mú láti ọ̀dọ̀ Eleasari àti ọ̀kan láti ọ̀dọ̀ Itamari.
6 O escriba Semeias, filho de Natanael, um levita, inscreveu-os em presença do rei e dos príncipes, do sacerdote Sadoc e de Aquimelec, filho de Abiatar, como também de chefes de famílias sacerdotais e levíticas, sendo uma família sorteada para Eleazar, em seguida, uma família para Itamar.
7 Ìpín èkínní jáde sí Jehoiaribu,
7 A primeira sorte caiu a Joiarib, a segunda a Jedei,
8 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sì ni Harimu,
8 a terceira a Harim, a quarta a Seorim,
9 ẹ̀karùnún sì ni Malkiah,
9 a quinta a Melquia, a sexta a Maimã,
10 èkeje sì ni Hakosi,
10 a sétima a Acos, a oitava a Abia,
11 ẹ̀kẹsànán sì ni Jeṣua,
11 a nona a Jesua, a décima a Sequenia,
12 ẹ̀kọkànlá sì ni Eliaṣibu,
12 a undécima a Eliasib, a duodécima a Jacim,
13 ẹ̀kẹtàlá sì ni Hupa,
13 a décima terceira a Hofa, a décima quarta a Isbaab,
14 ẹ̀kẹdógún sì ni Bilgah,
14 a décima quinta a Belga, a décima sexta a Emer,
15 ẹ̀kẹtàdínlógún sì ni Hesiri,
15 a décima sétima a Hezir, a décima oitava a Afses,
16 ẹ̀kọkàndínlógún sì ni Petahiah,
16 a décima nona a Fetéia, a vigésima a Ezequiel,
17 ẹ̀kọkànlélógún sì ni Jakini,
17 a vigésima primeira a Jaquim, a vigésima segunda a Gamul,
18 ẹ̀kẹtàlélógún sì ni Delaiah,
18 a vigésima terceira a Dalaiau, a vigésima quarta a Maziau.
19 Àwọn wọ̀nyí ni a yàn fún iṣẹ́ ìsìn nígbà tí wọ́n wọ ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ìlànà àti àṣẹ tí a ti fi fún wọn láti ọwọ́ baba ńlá wọn Aaroni gẹ́gẹ́ bí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí pàṣẹ fun un.
19 Assim, foram eles classificados para seus serviços no templo do Senhor, segundo as regras estabelecidas por Aarão, seu pai, consoante as ordens do Senhor, Deus de Israel.
20 Ìyókù àwọn ọmọ Lefi.
20 Dos restantes levitas, os chefes foram: dos filhos de Amrão: Subael; filho de Subael: Jeedeia;
21 Àti gẹ́gẹ́ bí Rehabiah, láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Rehabiah, Iṣiah sì ni alákọ́kọ́.
21 de Roodia, dos filhos de Roodia: o chefe Jesias.
22 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti;
22 Dos isaaritas: Salemot; dos filhos de Salemot: Jaat.
23 Àwọn ọmọ Hebroni:
23 Filhos de Hebron: Jeriau, Amarias, o segundo, Jaaziel, o terceiro, Jecmaã, o quarto.
24 Àwọn ọmọ Usieli: Mika;
24 Filho de Oziel: Mica; dos filhos de Mica: Samir;
25 Àwọn arákùnrin Mika: Iṣi;
25 irmão de Mica: Jesia; filho de Jesia: Zacarias.
26 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi.
26 Filhos de Merari: Mooli e Musi.
27 Àwọn ọmọ Merari.
27 Filhos de Merari, por Oziau, seu filho: Saão, Zacur e Hebri.
28 Láti Mahili: Eleasari, ẹni tí kò ni àwọn ọmọ.
28 De Mooli: Eleazar, que não teve filhos; de Cis, os filhos de Cis:
29 Láti Kiṣi. Àwọn ọmọ Kiṣi: Jerahmeeli.
29 Jerameel.
30 Àti àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti.
30 Filhos de Musi: Mooli, Eder e Jerimot.
31 Wọ́n sì ṣé kèké gẹ́gẹ́ bí àwọn arákùnrin wọn àwọn ọmọ Aaroni ṣe ṣẹ́, níwájú ọba Dafidi àti Sadoku, Ahimeleki, àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ìdílé àgbàgbà arákùnrin wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀ lórí àwọn arákùnrin wọn kéékèèké.
31 Estes são os filhos de Levi, segundo suas famílias.Também eles, como seus irmãos, os filhos de Aarão, foram tirados pela sorte, em presença do rei Davi, de Sadoc e Aquimelec, como também dos chefes de família dos sacerdotes e levitas, estando os mais velhos em mesma igualdade que os mais novos.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.