1 Crônicas 24

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARIB

Sair da comparação
ARIB Almeida Revisada Imprensa Bíblica
1 Àwọn wọ̀nyí sì ni pínpín àwọn ọmọ Aaroni.
1 As turmas dos filhos de Arão foram estas: os filhos de Arão: Nadabe, Abiú, Eleazar e Itamar.
2 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú kí ó tó di wí pé baba wọn kú, wọn kò sì ní àwọn ọmọ; bẹ́ẹ̀ ni Eleasari àti Itamari sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àlùfáà.
2 Mas Nadabe e Abiú morreram antes de seu pai, e não tiveram filhos; por isso Eleazar e Itamar exerciam o sacerdócio.
3 Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Sadoku ọmọ Eleasari àti Ahimeleki ọmọ Itamari, Dafidi sì yà wọ́n nípa nínú ìpín fún ìyàsọ́tọ̀ àwọn iṣẹ́ ìsìn wọn.
3 E Davi, juntamente com Zadoque, dos filhos de Eleazar, e com Aimeleque, dos filhos de Itamar, os distribuiu segundo os deveres do seu serviço.
4 A rí ọ̀pọ̀ àwọn olórí lára àwọn ọmọ Eleasari ju lára àwọn ọmọ Itamari lọ, wọ́n sì pín wọn lẹ́sẹ lẹ́sẹ: mẹ́rìndínlógún olórí láti ìdílé ọmọ Eleasari ìran wọn àti olórí méjọ ìdílé láti ara àwọn ọmọ Itamari.
4 E acharam-se mais chefes dentre os filhos de Eleazar do que dentre os filhos de Itamar; e assim foram distribuídos: dos filhos de Eleazar, chefes das casas paternas, dezesseis; e dos filhos de Itamar, segundo as suas casas paternas, oito.
5 Wọ́n sì pín wọn láìṣègbè nípa yíya ìpín, nítorí àwọn olórí ibi mímọ́ àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run wà láàrín àwọn ọmọ méjèèjì Eleasari àti Itamari.
5 Assim foram distribuídos por sortes, tanto uns como os outros; porque havia príncipes do santuário e príncipes de Deus, tanto dentre os filhos de Eleazar, como dentre os filhos de Itamar.
6 Ṣemaiah ọmọ Netaneli, akọ̀wé ọ̀kan lára àwọn ọmọ Lefi sì kọ orúkọ wọn níwájú ọba àti àwọn ìjòyè: Sadoku àlùfáà, Ahimeleki ọmọ Abiatari àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà tí a mú láti ọ̀dọ̀ Eleasari àti ọ̀kan láti ọ̀dọ̀ Itamari.
6 E os registrou Semaías, filho de Netanel, o escrivão dentre os levitas, diante do rei, dos príncipes, de Zadoque, o sacerdote, de Aimeleque, filho de Abiatar, e dos chefes das casas paternas entre os sacerdotes e entre os levitas, tomando-se uma casa paterna para Eleazar, e outra para Itamar.
7 Ìpín èkínní jáde sí Jehoiaribu,
7 Assim a primeira sorte saiu a Jeoiaribe, a segunda a Jedaías,
8 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sì ni Harimu,
8 a terceira a Harim, a quarta a Seorim,
9 ẹ̀karùnún sì ni Malkiah,
9 a quinta a Malquias, a sexta a Miamim,
10 èkeje sì ni Hakosi,
10 a sétima a Hacoz, a oitava a Abias,
11 ẹ̀kẹsànán sì ni Jeṣua,
11 a nona a Jesuá, a décima a Secanias,
12 ẹ̀kọkànlá sì ni Eliaṣibu,
12 a undécima a Eliasibe, a duodécima a Jaquim,
13 ẹ̀kẹtàlá sì ni Hupa,
13 a décima terceira a Hupá, a décima quarta a Jesebeabe,
14 ẹ̀kẹdógún sì ni Bilgah,
14 a décima quinta a Bilga, a décima sexta a Imer,
15 ẹ̀kẹtàdínlógún sì ni Hesiri,
15 a décima sétima a Hezir, a décima oitava a Hapizes,
16 ẹ̀kọkàndínlógún sì ni Petahiah,
16 a décima nona a Petaías, a vigésima a Jeezquel,
17 ẹ̀kọkànlélógún sì ni Jakini,
17 a vigésima primeira a Jaquim, a vigésima segunda a Gamul,
18 ẹ̀kẹtàlélógún sì ni Delaiah,
18 a vigésima terceira a Delaías, a vigésima quarta a Maazias.
19 Àwọn wọ̀nyí ni a yàn fún iṣẹ́ ìsìn nígbà tí wọ́n wọ ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ìlànà àti àṣẹ tí a ti fi fún wọn láti ọwọ́ baba ńlá wọn Aaroni gẹ́gẹ́ bí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí pàṣẹ fun un.
19 Esta foi a distribuição deles no seu serviço, para entrarem na casa do Senhor, segundo lhes fora ordenado por Arão, seu pai, como o Senhor Deus de Israel lhe tinha mandado.
20 Ìyókù àwọn ọmọ Lefi.
20 Do restante dos filhos de Levi: dos filhos de Anrão, Subael; dos filhos de Subael, Jedeías.
21 Àti gẹ́gẹ́ bí Rehabiah, láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Rehabiah, Iṣiah sì ni alákọ́kọ́.
21 Quanto a Reabias: dos filhos de Reabias, Issijá o chefe;
22 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti;
22 dos izaritas, Selomote; dos filhos de Selomote, Jaate;
23 Àwọn ọmọ Hebroni:
23 dos filhos de Hebrom: Jerias o chefe, Amarias o segundo, Jaaziel o terceiro, Jecameão o quarto;
24 Àwọn ọmọ Usieli: Mika;
24 dos filhos de Uziel, Mica; dos filhos de Mica, Samir;
25 Àwọn arákùnrin Mika: Iṣi;
25 o irmão de Mica, Issijá; dos filhos de Issijá, Zacarias.
26 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi.
26 Os filhos de Merári, Mali e Musi; dos filhos de Jaazias, Beno;
27 Àwọn ọmọ Merari.
27 os filhos de Merári: de Jaazias: Beno, Soão, Zacur e Ibri;
28 Láti Mahili: Eleasari, ẹni tí kò ni àwọn ọmọ.
28 de Mali, Eleazar; e este não teve filhos.
29 Láti Kiṣi. Àwọn ọmọ Kiṣi: Jerahmeeli.
29 Quanto a Quis: dos filhos de Quis, Jerameel;
30 Àti àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti.
30 e os filhos de Musi: Mali, Eder e Jerimote. Esses foram os filhos dos levitas, segundo as suas casas paternas.
31 Wọ́n sì ṣé kèké gẹ́gẹ́ bí àwọn arákùnrin wọn àwọn ọmọ Aaroni ṣe ṣẹ́, níwájú ọba Dafidi àti Sadoku, Ahimeleki, àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ìdílé àgbàgbà arákùnrin wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀ lórí àwọn arákùnrin wọn kéékèèké.
31 Estes também, como seus irmãos, os filhos de Arão, lançaram sortes diante do rei Davi, de Zadoque, de Aimeleque, e dos chefes das casas paternas entre os sacerdotes e entre os levitas; assim fizeram, tanto para o chefe de casa paterna, como para o seu irmão menor.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.