1 Crônicas 24

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARC

Sair da comparação
ARC Almeida Revista e Corrigida 2009
1 Àwọn wọ̀nyí sì ni pínpín àwọn ọmọ Aaroni.
1 E, quanto aos filhos de Arão, estas foram as suas divisões; os filhos de Arão foram Nadabe, e Abiú, e Eleazar, e Itamar.
2 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú kí ó tó di wí pé baba wọn kú, wọn kò sì ní àwọn ọmọ; bẹ́ẹ̀ ni Eleasari àti Itamari sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àlùfáà.
2 E morreram Nadabe e Abiú antes de seu pai e não tiveram filhos; e Eleazar e Itamar administravam o sacerdócio.
3 Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Sadoku ọmọ Eleasari àti Ahimeleki ọmọ Itamari, Dafidi sì yà wọ́n nípa nínú ìpín fún ìyàsọ́tọ̀ àwọn iṣẹ́ ìsìn wọn.
3 E Davi os repartiu, como também a Zadoque, dos filhos de Eleazar, e a Aimeleque, dos filhos de Itamar, segundo o seu ofício no seu ministério.
4 A rí ọ̀pọ̀ àwọn olórí lára àwọn ọmọ Eleasari ju lára àwọn ọmọ Itamari lọ, wọ́n sì pín wọn lẹ́sẹ lẹ́sẹ: mẹ́rìndínlógún olórí láti ìdílé ọmọ Eleasari ìran wọn àti olórí méjọ ìdílé láti ara àwọn ọmọ Itamari.
4 E achou-se que eram muitos mais os filhos de Eleazar entre os chefes de famílias do que os filhos de Itamar, quando os repartiram; dos filhos de Eleazar, dezesseis chefes das casas dos pais, mas dos filhos de Itamar, segundo as casas de seus pais, oito.
5 Wọ́n sì pín wọn láìṣègbè nípa yíya ìpín, nítorí àwọn olórí ibi mímọ́ àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run wà láàrín àwọn ọmọ méjèèjì Eleasari àti Itamari.
5 E os repartiram por sortes, uns com os outros; porque houve maiorais do santuário e maiorais da Casa de Deus, assim dentre os filhos de Eleazar, como dentre os filhos de Itamar.
6 Ṣemaiah ọmọ Netaneli, akọ̀wé ọ̀kan lára àwọn ọmọ Lefi sì kọ orúkọ wọn níwájú ọba àti àwọn ìjòyè: Sadoku àlùfáà, Ahimeleki ọmọ Abiatari àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà tí a mú láti ọ̀dọ̀ Eleasari àti ọ̀kan láti ọ̀dọ̀ Itamari.
6 E os registrou Semaías, filho de Natanael, o escrivão dentre os levitas, perante o rei, e os príncipes, e Zadoque, o sacerdote, e Aimeleque, filho de Abiatar, e os chefes dos pais entre os sacerdotes e entre os levitas; uma dentre as casas dos pais se tomou para Eleazar, e se tomou outra para Itamar.
7 Ìpín èkínní jáde sí Jehoiaribu,
7 E saiu a primeira sorte a Jeoiaribe, a segunda, a Jedaías;
8 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sì ni Harimu,
8 a terceira, a Harim; a quarta, a Seorim;
9 ẹ̀karùnún sì ni Malkiah,
9 a quinta, a Malquias; a sexta, a Miamim;
10 èkeje sì ni Hakosi,
10 a sétima, a Hacoz; a oitava, a Abias;
11 ẹ̀kẹsànán sì ni Jeṣua,
11 a nona, a Jesua; a décima, a Secanias;
12 ẹ̀kọkànlá sì ni Eliaṣibu,
12 a undécima, a Eliasibe; a duodécima, a Jaquim;
13 ẹ̀kẹtàlá sì ni Hupa,
13 a décima terceira, a Hupá; a décima quarta, a Jesebeabe;
14 ẹ̀kẹdógún sì ni Bilgah,
14 a décima quinta, a Bilga; a décima sexta, a Imer;
15 ẹ̀kẹtàdínlógún sì ni Hesiri,
15 a décima sétima a Hezir; a décima oitava, a Hapises;
16 ẹ̀kọkàndínlógún sì ni Petahiah,
16 a décima nona, a Petaías; a vigésima, a Jeezquel;
17 ẹ̀kọkànlélógún sì ni Jakini,
17 a vigésima primeira, a Jaquim; a vigésima segunda, a Gamul;
18 ẹ̀kẹtàlélógún sì ni Delaiah,
18 a vigésima terceira, a Delaías; a vigésima quarta, a Maazias.
19 Àwọn wọ̀nyí ni a yàn fún iṣẹ́ ìsìn nígbà tí wọ́n wọ ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ìlànà àti àṣẹ tí a ti fi fún wọn láti ọwọ́ baba ńlá wọn Aaroni gẹ́gẹ́ bí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí pàṣẹ fun un.
19 O ofício destes, no seu ministério, era entrar na Casa do Senhor , segundo lhes fora ordenado por Arão, seu pai, como o Senhor , Deus de Israel, lhe tinha ordenado.
20 Ìyókù àwọn ọmọ Lefi.
20 E do resto dos filhos de Levi: dos filhos de Anrão, Subael; dos filhos de Subael, Jedias;
21 Àti gẹ́gẹ́ bí Rehabiah, láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Rehabiah, Iṣiah sì ni alákọ́kọ́.
21 dos filhos de Reabias: Issias era o chefe;
22 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti;
22 dos isaritas, Selomite; dos filhos de Selomite, Jaate;
23 Àwọn ọmọ Hebroni:
23 dos filhos de Hebrom, Jerias, o primeiro, Amarias, o segundo, Jaaziel, o terceiro, Jecameão, o quarto;
24 Àwọn ọmọ Usieli: Mika;
24 dos filhos de Uziel, Mica; dos filhos de Mica, Samir;
25 Àwọn arákùnrin Mika: Iṣi;
25 o irmão de Mica, Issias; dos filhos de Issias, Zacarias;
26 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi.
26 dos filhos de Merari, Mali e Musi; dos filhos de Jaazias, Beno;
27 Àwọn ọmọ Merari.
27 dos filhos de Merari, da parte de Jaazias, Beno, e Soão, e Zacur, e Ibri;
28 Láti Mahili: Eleasari, ẹni tí kò ni àwọn ọmọ.
28 de Mali, Eleazar; este não teve filhos;
29 Láti Kiṣi. Àwọn ọmọ Kiṣi: Jerahmeeli.
29 dos filhos de Quis, Jerameel;
30 Àti àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti.
30 dos filhos de Musi, Mali, e Éder, e Jerimote; estes foram os filhos dos levitas, segundo as suas casas paternas.
31 Wọ́n sì ṣé kèké gẹ́gẹ́ bí àwọn arákùnrin wọn àwọn ọmọ Aaroni ṣe ṣẹ́, níwájú ọba Dafidi àti Sadoku, Ahimeleki, àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ìdílé àgbàgbà arákùnrin wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀ lórí àwọn arákùnrin wọn kéékèèké.
31 E o chefe da casa dos pais e bem assim como um de seus irmãos menores lançaram sortes igualmente como seus irmãos, os filhos de Arão, perante o rei Davi, e Zadoque, e Aimeleque, e os chefes dos pais entre os sacerdotes e entre os levitas.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.