1 Crônicas 24
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARA
1 Àwọn wọ̀nyí sì ni pínpín àwọn ọmọ Aaroni.
1 Quanto aos filhos de Arão, foram eles divididos por seus turnos. Filhos de Arão: Nadabe, Abiú, Eleazar e Itamar.
2 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú kí ó tó di wí pé baba wọn kú, wọn kò sì ní àwọn ọmọ; bẹ́ẹ̀ ni Eleasari àti Itamari sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àlùfáà.
2 Nadabe e Abiú morreram antes de seu pai e não tiveram filhos; Eleazar e Itamar oficiavam como sacerdotes.
3 Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Sadoku ọmọ Eleasari àti Ahimeleki ọmọ Itamari, Dafidi sì yà wọ́n nípa nínú ìpín fún ìyàsọ́tọ̀ àwọn iṣẹ́ ìsìn wọn.
3 Davi, com Zadoque, dos filhos de Eleazar, e com Aimeleque, dos filhos de Itamar, os dividiu segundo os seus deveres no seu ministério.
4 A rí ọ̀pọ̀ àwọn olórí lára àwọn ọmọ Eleasari ju lára àwọn ọmọ Itamari lọ, wọ́n sì pín wọn lẹ́sẹ lẹ́sẹ: mẹ́rìndínlógún olórí láti ìdílé ọmọ Eleasari ìran wọn àti olórí méjọ ìdílé láti ara àwọn ọmọ Itamari.
4 E achou-se que eram mais os filhos de Eleazar entre os chefes de famílias do que os filhos de Itamar, quando os dividiram; dos filhos de Eleazar, dezesseis chefes de famílias; dos filhos de Itamar, oito.
5 Wọ́n sì pín wọn láìṣègbè nípa yíya ìpín, nítorí àwọn olórí ibi mímọ́ àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run wà láàrín àwọn ọmọ méjèèjì Eleasari àti Itamari.
5 Repartiram-nos por sortes, uns como os outros; porque havia príncipes do santuário e príncipes de Deus, tanto dos filhos de Eleazar como dos filhos de Itamar.
6 Ṣemaiah ọmọ Netaneli, akọ̀wé ọ̀kan lára àwọn ọmọ Lefi sì kọ orúkọ wọn níwájú ọba àti àwọn ìjòyè: Sadoku àlùfáà, Ahimeleki ọmọ Abiatari àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà tí a mú láti ọ̀dọ̀ Eleasari àti ọ̀kan láti ọ̀dọ̀ Itamari.
6 Semaías, escrivão, filho de Natanael, levita, registrou-os na presença do rei, dos príncipes, do sacerdote Zadoque, de Aimeleque, filho de Abiatar, e dos cabeças das famílias dos sacerdotes e dos levitas; sendo escolhidas as famílias, por sorte, alternadamente, para Eleazar e para Itamar.
7 Ìpín èkínní jáde sí Jehoiaribu,
7 Saiu a primeira sorte a Jeoiaribe; a segunda, a Jedaías;
8 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sì ni Harimu,
8 a terceira, a Harim; a quarta, a Seorim;
9 ẹ̀karùnún sì ni Malkiah,
9 a quinta, a Malquias; a sexta, a Miamim;
10 èkeje sì ni Hakosi,
10 a sétima, a Hacoz; a oitava, a Abias;
11 ẹ̀kẹsànán sì ni Jeṣua,
11 a nona, a Jesua; a décima, a Secanias;
12 ẹ̀kọkànlá sì ni Eliaṣibu,
12 a undécima, a Eliasibe; a duodécima, a Jaquim;
13 ẹ̀kẹtàlá sì ni Hupa,
13 a décima terceira, a Hupá; a décima quarta, a Jesebeabe;
14 ẹ̀kẹdógún sì ni Bilgah,
14 a décima quinta, a Bilga; a décima sexta, a Imer;
15 ẹ̀kẹtàdínlógún sì ni Hesiri,
15 a décima sétima, a Hezir; a décima oitava, a Hapises;
16 ẹ̀kọkàndínlógún sì ni Petahiah,
16 a décima nona, a Petaías; a vigésima, a Jeezquel;
17 ẹ̀kọkànlélógún sì ni Jakini,
17 a vigésima primeira, a Jaquim; a vigésima segunda, a Gamul;
18 ẹ̀kẹtàlélógún sì ni Delaiah,
18 a vigésima terceira, a Delaías; a vigésima quarta, a Maazias.
19 Àwọn wọ̀nyí ni a yàn fún iṣẹ́ ìsìn nígbà tí wọ́n wọ ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ìlànà àti àṣẹ tí a ti fi fún wọn láti ọwọ́ baba ńlá wọn Aaroni gẹ́gẹ́ bí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí pàṣẹ fun un.
19 O ofício destes no seu ministério era entrar na Casa do Senhor , segundo a maneira estabelecida por Arão, seu pai, como o Senhor , Deus de Israel, lhe ordenara.
20 Ìyókù àwọn ọmọ Lefi.
20 Eis os chefes do restante dos filhos de Levi: dos filhos de Anrão, Subael; dos filhos de Subael, Jedias;
21 Àti gẹ́gẹ́ bí Rehabiah, láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Rehabiah, Iṣiah sì ni alákọ́kọ́.
21 dos filhos de Reabias, Issias, o chefe;
22 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti;
22 dos isaritas, Selomite; dos filhos de Selomite, Jaate;
23 Àwọn ọmọ Hebroni:
23 dos filhos de Hebrom, Jerias, o primeiro, Amarias, o segundo, Jaaziel, o terceiro, Jecameão, o quarto;
24 Àwọn ọmọ Usieli: Mika;
24 dos filhos de Uziel, Mica; dos filhos de Mica, Samir;
25 Àwọn arákùnrin Mika: Iṣi;
25 o irmão de Mica, Issias; dos filhos de Issias, Zacarias;
26 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi.
26 dos filhos de Merari, Mali e Musi; dos filhos de Jaazias, Beno;
27 Àwọn ọmọ Merari.
27 dos filhos de Merari, da parte de Jaazias: Beno, Soão, Zacur e Ibri;
28 Láti Mahili: Eleasari, ẹni tí kò ni àwọn ọmọ.
28 de Mali, Eleazar, que não teve filhos;
29 Láti Kiṣi. Àwọn ọmọ Kiṣi: Jerahmeeli.
29 dos filhos de Quis, Jerameel;
30 Àti àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti.
30 dos filhos de Musi, Mali, Éder e Jerimote. Foram estes os filhos dos levitas, segundo as suas famílias.
31 Wọ́n sì ṣé kèké gẹ́gẹ́ bí àwọn arákùnrin wọn àwọn ọmọ Aaroni ṣe ṣẹ́, níwájú ọba Dafidi àti Sadoku, Ahimeleki, àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ìdílé àgbàgbà arákùnrin wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀ lórí àwọn arákùnrin wọn kéékèèké.
31 Também estes, tanto os chefes das famílias como os seus irmãos menores, como fizeram os outros seus irmãos, filhos de Arão, lançaram sortes na presença do rei Davi, de Zadoque, de Aimeleque e dos cabeças das famílias dos sacerdotes e dos levitas.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.