1 Crônicas 24
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH
1 Àwọn wọ̀nyí sì ni pínpín àwọn ọmọ Aaroni.
1 São estes os grupos aos quais pertenciam os descendentes de Arão. Arão foi pai de quatro filhos: Nadabe, Abiú, Eleazar e Itamar.
2 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú kí ó tó di wí pé baba wọn kú, wọn kò sì ní àwọn ọmọ; bẹ́ẹ̀ ni Eleasari àti Itamari sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àlùfáà.
2 Nadabe e Abiú morreram antes do seu pai; eles não deixaram filhos, e por isso os seus irmãos Eleazar e Itamar se tornaram sacerdotes.
3 Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Sadoku ọmọ Eleasari àti Ahimeleki ọmọ Itamari, Dafidi sì yà wọ́n nípa nínú ìpín fún ìyàsọ́tọ̀ àwọn iṣẹ́ ìsìn wọn.
3 O rei Davi organizou os descendentes de Arão de acordo com os seus deveres. Foi ajudado nesse trabalho por Zadoque, que era descendente de Eleazar, e por Aimeleque, que era descendente de Itamar.
4 A rí ọ̀pọ̀ àwọn olórí lára àwọn ọmọ Eleasari ju lára àwọn ọmọ Itamari lọ, wọ́n sì pín wọn lẹ́sẹ lẹ́sẹ: mẹ́rìndínlógún olórí láti ìdílé ọmọ Eleasari ìran wọn àti olórí méjọ ìdílé láti ara àwọn ọmọ Itamari.
4 Os descendentes de Eleazar foram divididos em dezesseis grupos, e os descendentes de Itamar foram divididos em oito. Isso foi feito assim porque entre os descendentes de Eleazar havia um número maior de chefes de famílias.
5 Wọ́n sì pín wọn láìṣègbè nípa yíya ìpín, nítorí àwọn olórí ibi mímọ́ àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run wà láàrín àwọn ọmọ méjèèjì Eleasari àti Itamari.
5 Como havia oficiais do Templo e líderes espirituais tanto entre os descendentes de Eleazar como entre os de Itamar, eles foram divididos por sorteio .
6 Ṣemaiah ọmọ Netaneli, akọ̀wé ọ̀kan lára àwọn ọmọ Lefi sì kọ orúkọ wọn níwájú ọba àti àwọn ìjòyè: Sadoku àlùfáà, Ahimeleki ọmọ Abiatari àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà tí a mú láti ọ̀dọ̀ Eleasari àti ọ̀kan láti ọ̀dọ̀ Itamari.
6 Os descendentes de Eleazar e de Itamar eram sorteados alternadamente, e os seus nomes foram escritos num livro pelo escrivão Semaías, filho de Netanel. Foram testemunhas o rei, os seus oficiais, o sacerdote Zadoque, Aimeleque, filho de Abiatar, e os chefes das famílias de sacerdotes e das famílias de levitas .
7 Ìpín èkínní jáde sí Jehoiaribu,
7 — ausente —
8 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sì ni Harimu,
8 — ausente —
9 ẹ̀karùnún sì ni Malkiah,
9 — ausente —
10 èkeje sì ni Hakosi,
10 — ausente —
11 ẹ̀kẹsànán sì ni Jeṣua,
11 — ausente —
12 ẹ̀kọkànlá sì ni Eliaṣibu,
12 — ausente —
13 ẹ̀kẹtàlá sì ni Hupa,
13 — ausente —
14 ẹ̀kẹdógún sì ni Bilgah,
14 — ausente —
15 ẹ̀kẹtàdínlógún sì ni Hesiri,
15 — ausente —
16 ẹ̀kọkàndínlógún sì ni Petahiah,
16 — ausente —
17 ẹ̀kọkànlélógún sì ni Jakini,
17 — ausente —
18 ẹ̀kẹtàlélógún sì ni Delaiah,
18 — ausente —
19 Àwọn wọ̀nyí ni a yàn fún iṣẹ́ ìsìn nígbà tí wọ́n wọ ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ìlànà àti àṣẹ tí a ti fi fún wọn láti ọwọ́ baba ńlá wọn Aaroni gẹ́gẹ́ bí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí pàṣẹ fun un.
19 Os nomes desses homens foram escritos num livro, de acordo com os seus turnos, para entrarem no Templo e cumprirem os deveres conforme as regras deixadas por Arão, o seu antepassado, conforme o Senhor , o Deus de Israel, lhe havia ordenado.
20 Ìyókù àwọn ọmọ Lefi.
20 São estes os outros chefes de famílias dos descendentes de Levi: Jedias, descendente de Anrão através de Sebuel;
21 Àti gẹ́gẹ́ bí Rehabiah, láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Rehabiah, Iṣiah sì ni alákọ́kọ́.
21 Issias, descendente de Reabias;
22 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti;
22 Jaate, descendente de Isar através de Selomite;
23 Àwọn ọmọ Hebroni:
23 Jerias, Amariá, Jaaziel e Jecameão, filhos de Hebrom, por ordem de idade;
24 Àwọn ọmọ Usieli: Mika;
24 Samir, descendente de Uziel, através de Mica;
25 Àwọn arákùnrin Mika: Iṣi;
25 Zacarias, descendente de Uziel, através de Issias, irmão de Mica;
26 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi.
26 Mali, Musi e Jaazias, descendentes de Merari.
27 Àwọn ọmọ Merari.
27 Jaazias foi pai de três filhos: Soão, Zacur e Ibri. Mali foi pai de dois filhos: Eleazar e Quis. Eleazar não deixou filhos, porém Quis foi pai de um filho chamado Jerameel.
28 Láti Mahili: Eleasari, ẹni tí kò ni àwọn ọmọ.
28 — ausente —
29 Láti Kiṣi. Àwọn ọmọ Kiṣi: Jerahmeeli.
29 — ausente —
30 Àti àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti.
30 Musi foi pai de três filhos: Mali, Éder e Jerimote. Eram estas as famílias dos
31 Wọ́n sì ṣé kèké gẹ́gẹ́ bí àwọn arákùnrin wọn àwọn ọmọ Aaroni ṣe ṣẹ́, níwájú ọba Dafidi àti Sadoku, Ahimeleki, àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ìdílé àgbàgbà arákùnrin wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀ lórí àwọn arákùnrin wọn kéékèèké.
31 O chefe de cada família e um dos seus irmãos mais novos tiraram sortes para serem escalados como haviam feito os seus parentes, os sacerdotes descendentes de Arão. Foram testemunhas o rei Davi, Zadoque, Aimeleque e os chefes de famílias de sacerdotes e de levitas.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.