1 Crônicas 24
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Àwọn wọ̀nyí sì ni pínpín àwọn ọmọ Aaroni.
1 Ora estas são as divisões dos filhos de Arão. Os filhos de Arão: Nadabe e Abiú, Eleazar, e Itamar.
2 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú kí ó tó di wí pé baba wọn kú, wọn kò sì ní àwọn ọmọ; bẹ́ẹ̀ ni Eleasari àti Itamari sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àlùfáà.
2 Porém, Nadabe e Abiú morreram antes do seu pai, e não tiveram filhos; por isso Eleazar e Itamar cumpriram o ofício sacerdotal.
3 Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Sadoku ọmọ Eleasari àti Ahimeleki ọmọ Itamari, Dafidi sì yà wọ́n nípa nínú ìpín fún ìyàsọ́tọ̀ àwọn iṣẹ́ ìsìn wọn.
3 E Davi os distribuiu, tanto Zadoque, dos filhos de Eleazar; como Aimeleque, dos filhos de Itamar, segundo os seus ofícios no seu serviço.
4 A rí ọ̀pọ̀ àwọn olórí lára àwọn ọmọ Eleasari ju lára àwọn ọmọ Itamari lọ, wọ́n sì pín wọn lẹ́sẹ lẹ́sẹ: mẹ́rìndínlógún olórí láti ìdílé ọmọ Eleasari ìran wọn àti olórí méjọ ìdílé láti ara àwọn ọmọ Itamari.
4 E havia mais chefes encontrados nos filhos de Eleazar do que nos filhos de Itamar e eles foram divididos. Entre os filhos de Eleazar havia dezesseis chefes da casa dos seus pais, e oito entre os filhos de Itamar, segundo a casa dos seus pais.
5 Wọ́n sì pín wọn láìṣègbè nípa yíya ìpín, nítorí àwọn olórí ibi mímọ́ àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run wà láàrín àwọn ọmọ méjèèjì Eleasari àti Itamari.
5 Assim, eles foram divididos por sorteio, um tirou sorte com outro; porque os governadores do santuário, e os regentes da casa de Deus, eram dos filhos de Eleazar, e dos filhos de Itamar.
6 Ṣemaiah ọmọ Netaneli, akọ̀wé ọ̀kan lára àwọn ọmọ Lefi sì kọ orúkọ wọn níwájú ọba àti àwọn ìjòyè: Sadoku àlùfáà, Ahimeleki ọmọ Abiatari àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà tí a mú láti ọ̀dọ̀ Eleasari àti ọ̀kan láti ọ̀dọ̀ Itamari.
6 E Semaías, o filho de Natanael, o escriba, um dos levitas, registrou-os diante do rei, e dos príncipes, e de Zadoque, o sacerdote, e Aimeleque, o filho de Abiatar; e diante do chefe dos pais dos sacerdotes e levitas; uma casa principal sendo tomada para Eleazar, e uma para Itamar.
7 Ìpín èkínní jáde sí Jehoiaribu,
7 Ora, a primeira sorte saiu para Jeoiaribe, a segunda para Jedaías;
8 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sì ni Harimu,
8 a terceira para Harim, a quarta para Seorim;
9 ẹ̀karùnún sì ni Malkiah,
9 a quinta para Malquias, a sexta para Miamim;
10 èkeje sì ni Hakosi,
10 a sétima para Hacoz, a oitava para Abias,
11 ẹ̀kẹsànán sì ni Jeṣua,
11 a nona para Jesuá, a décima para Secanias,
12 ẹ̀kọkànlá sì ni Eliaṣibu,
12 a undécima para Eliasibe, a duodécima para Jaquim,
13 ẹ̀kẹtàlá sì ni Hupa,
13 a décima terceira para Hupá, a décima quarta para Jesebeabe;
14 ẹ̀kẹdógún sì ni Bilgah,
14 a décima quinta para Bilga, a décima sexta para Imer,
15 ẹ̀kẹtàdínlógún sì ni Hesiri,
15 a décima sétima para Hezir, a décima oitava para Hapises,
16 ẹ̀kọkàndínlógún sì ni Petahiah,
16 a décima nona para Petaías, a vigésima para Jeezquel;
17 ẹ̀kọkànlélógún sì ni Jakini,
17 vigésima primeira para Jaquim, a vigésima segunda para Gamul,
18 ẹ̀kẹtàlélógún sì ni Delaiah,
18 a vigésima terceira para Delaías; a vigésima quarta para Maazias.
19 Àwọn wọ̀nyí ni a yàn fún iṣẹ́ ìsìn nígbà tí wọ́n wọ ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ìlànà àti àṣẹ tí a ti fi fún wọn láti ọwọ́ baba ńlá wọn Aaroni gẹ́gẹ́ bí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí pàṣẹ fun un.
19 Estas foram as suas incumbências no serviço por vir na casa do SENHOR, segundo lhes fora ordenado por Arão seu pai, como o SENHOR Deus de Israel lhe havia ordenado.
20 Ìyókù àwọn ọmọ Lefi.
20 E o restante dos filhos de Levi foram estes: dos filhos de Anrão, Subael; dos filhos de Subael: Jedias.
21 Àti gẹ́gẹ́ bí Rehabiah, láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Rehabiah, Iṣiah sì ni alákọ́kọ́.
21 Acerca de Reabias: dos filhos de Reabias, o primeiro foi Issias.
22 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti;
22 Dos Isaritas: Selomite, dos filhos de Selomite: Jaate.
23 Àwọn ọmọ Hebroni:
23 Dos filhos de Hebrom: Jerias, o primeiro; Amarias, o segundo; Jaaziel, o terceiro, e Jecameão, o quarto.
24 Àwọn ọmọ Usieli: Mika;
24 Dos filhos de Uziel: Mica; dos filhos de Mica: Samir.
25 Àwọn arákùnrin Mika: Iṣi;
25 O irmão de Mica foi Issias; dos filhos de Issias: Zacarias.
26 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi.
26 Os filhos de Merari foram Mali e Musi; os filhos de Jaazias: Beno.
27 Àwọn ọmọ Merari.
27 Os filhos de Merari, por Jaazias: Beno e Soão, e Zacur, e Ibri.
28 Láti Mahili: Eleasari, ẹni tí kò ni àwọn ọmọ.
28 De Mali vieram: Eleazar, que não tinha filhos.
29 Láti Kiṣi. Àwọn ọmọ Kiṣi: Jerahmeeli.
29 Quanto a Quis: o filho de Quis foi Jerameel.
30 Àti àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti.
30 Também os filhos de Musi: Mali, e Éder, e Jerimote. Estes foram os filhos dos levitas segundo a casa dos seus pais.
31 Wọ́n sì ṣé kèké gẹ́gẹ́ bí àwọn arákùnrin wọn àwọn ọmọ Aaroni ṣe ṣẹ́, níwájú ọba Dafidi àti Sadoku, Ahimeleki, àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ìdílé àgbàgbà arákùnrin wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀ lórí àwọn arákùnrin wọn kéékèèké.
31 Estes como seus irmãos, filhos de Arão, também lançaram sorte na presença do rei Davi, de Zadoque, de Aimeleque e dos cabeças das famílias dos sacerdotes e dos levitas. Assim fizeram tanto as famílias do chefe como as do irmão mais moço.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.