1 Crônicas 24
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NVI
1 Àwọn wọ̀nyí sì ni pínpín àwọn ọmọ Aaroni.
1 Os filhos de Arão foram assim agrupados: Os filhos de Arão foram Nadabe, Abiú, Eleazar e Itamar.
2 Ṣùgbọ́n Nadabu àti Abihu kú kí ó tó di wí pé baba wọn kú, wọn kò sì ní àwọn ọmọ; bẹ́ẹ̀ ni Eleasari àti Itamari sì ṣe gẹ́gẹ́ bí àlùfáà.
2 Mas Nadabe e Abiú morreram antes de seu pai e não tiveram filhos; apenas Eleazar e Itamar serviram como sacerdotes.
3 Pẹ̀lú ìrànlọ́wọ́ Sadoku ọmọ Eleasari àti Ahimeleki ọmọ Itamari, Dafidi sì yà wọ́n nípa nínú ìpín fún ìyàsọ́tọ̀ àwọn iṣẹ́ ìsìn wọn.
3 Com a ajuda de Zadoque, descendente de Eleazar, e de Aimeleque, descendente de Itamar, Davi os dividiu em grupos para que cumprissem as suas responsabilidades.
4 A rí ọ̀pọ̀ àwọn olórí lára àwọn ọmọ Eleasari ju lára àwọn ọmọ Itamari lọ, wọ́n sì pín wọn lẹ́sẹ lẹ́sẹ: mẹ́rìndínlógún olórí láti ìdílé ọmọ Eleasari ìran wọn àti olórí méjọ ìdílé láti ara àwọn ọmọ Itamari.
4 Havia um número maior de chefes de família entre os descendentes de Eleazar do que entre os de Itamar, e por isso eles foram assim divididos: dezesseis chefes de famílias dentre os descendentes de Eleazar e oito, dentre os descendentes de Itamar.
5 Wọ́n sì pín wọn láìṣègbè nípa yíya ìpín, nítorí àwọn olórí ibi mímọ́ àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run wà láàrín àwọn ọmọ méjèèjì Eleasari àti Itamari.
5 Eles foram divididos de maneira imparcial mediante sorteio, pois havia líderes do santuário e líderes de Deus tanto entre os descendentes de Eleazar como entre os de Itamar.
6 Ṣemaiah ọmọ Netaneli, akọ̀wé ọ̀kan lára àwọn ọmọ Lefi sì kọ orúkọ wọn níwájú ọba àti àwọn ìjòyè: Sadoku àlùfáà, Ahimeleki ọmọ Abiatari àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà tí a mú láti ọ̀dọ̀ Eleasari àti ọ̀kan láti ọ̀dọ̀ Itamari.
6 O escriba Semaías, filho do levita Natanael, registrou os nomes deles na presença do rei, dos líderes, dos sacerdotes Zadoque e Aimeleque, filho de Abiatar, e dos chefes de famílias dos sacerdotes e dos levitas; as famílias de Eleazar e de Itamar foram sorteadas alternadamente.
7 Ìpín èkínní jáde sí Jehoiaribu,
7 A primeira sorte caiu para Jeoiaribe, a segunda para Jedaías,
8 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sì ni Harimu,
8 a terceira para Harim, a quarta para Seorim,
9 ẹ̀karùnún sì ni Malkiah,
9 a quinta para Malquias, a sexta para Miamim,
10 èkeje sì ni Hakosi,
10 a sétima para Hacoz, a oitava para Abias,
11 ẹ̀kẹsànán sì ni Jeṣua,
11 a nona para Jesua, a décima para Secanias,
12 ẹ̀kọkànlá sì ni Eliaṣibu,
12 a décima primeira para Eliasibe, a décima segunda para Jaquim,
13 ẹ̀kẹtàlá sì ni Hupa,
13 a décima terceira para Hupá, a décima quarta para Jesebeabe,
14 ẹ̀kẹdógún sì ni Bilgah,
14 a décima quinta para Bilga, a décima sexta para Imer,
15 ẹ̀kẹtàdínlógún sì ni Hesiri,
15 a décima sétima para Hezir, a décima oitava para Hapises,
16 ẹ̀kọkàndínlógún sì ni Petahiah,
16 a décima nona para Petaías, a vigésima para Jeezquel,
17 ẹ̀kọkànlélógún sì ni Jakini,
17 a vigésima primeira para Jaquim, a vigésima segunda para Gamul,
18 ẹ̀kẹtàlélógún sì ni Delaiah,
18 a vigésima terceira para Delaías, e a vigésima quarta para Maazias.
19 Àwọn wọ̀nyí ni a yàn fún iṣẹ́ ìsìn nígbà tí wọ́n wọ ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ìlànà àti àṣẹ tí a ti fi fún wọn láti ọwọ́ baba ńlá wọn Aaroni gẹ́gẹ́ bí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí pàṣẹ fun un.
19 Conforme essa ordem eles deveriam ministrar quando entrassem no templo do Senhor, de acordo com as prescrições que Arão, antepassado deles, lhes deixou, conforme o Senhor, o Deus de Israel, havia lhe ordenado.
20 Ìyókù àwọn ọmọ Lefi.
20 Estes foram os chefes dos outros levitas: dos descendentes de Anrão: Subael; dos descendentes de Subael: Jedias.
21 Àti gẹ́gẹ́ bí Rehabiah, láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Rehabiah, Iṣiah sì ni alákọ́kọ́.
21 Quanto a Reabias, Issias foi o chefe dos seus filhos.
22 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti;
22 Dos descendentes de Isar: Selomote; dos filhos de Selomote: Jaate.
23 Àwọn ọmọ Hebroni:
23 Dos descendentes de Hebrom: Jerias, o primeiro, Amarias, o segundo, Jaaziel, o terceiro, e Jecameão, o quarto.
24 Àwọn ọmọ Usieli: Mika;
24 Dos descendentes de Uziel: Mica; dos filhos de Mica: Samir.
25 Àwọn arákùnrin Mika: Iṣi;
25 Dos descendentes de Issias, irmão de Mica, Zacarias.
26 Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi.
26 Dos filhos de Merari: Mali e Musi. Dos filhos de Jaazias: Beno.
27 Àwọn ọmọ Merari.
27 Os descendentes de Merari por Jaazias: Beno, Soão, Zacur e Ibri.
28 Láti Mahili: Eleasari, ẹni tí kò ni àwọn ọmọ.
28 De Mali: Eleazar, que não teve filhos.
29 Láti Kiṣi. Àwọn ọmọ Kiṣi: Jerahmeeli.
29 De Quis: Jerameel.
30 Àti àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti.
30 E foram estes os filhos de Musi: Mali, Éder e Jeremote. Esses foram os levitas, de acordo com as suas famílias.
31 Wọ́n sì ṣé kèké gẹ́gẹ́ bí àwọn arákùnrin wọn àwọn ọmọ Aaroni ṣe ṣẹ́, níwájú ọba Dafidi àti Sadoku, Ahimeleki, àti olórí ìdílé àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ìdílé àgbàgbà arákùnrin wọ́n sì ṣe bẹ́ẹ̀ lórí àwọn arákùnrin wọn kéékèèké.
31 Eles também tiraram sortes na presença do rei Davi e de Zadoque, de Aimeleque, e dos chefes de famílias dos sacerdotes e dos levitas, assim como fizeram seus irmãos, os descendentes de Arão. As famílias dos irmãos mais velhos foram tratadas da mesma maneira que as dos mais novos.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.