1 Crônicas 1
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs VC
1 Adamu, Seti, Enoṣi,
1 Adão, Set, Enós,
2 Kenani, Mahalaleli, Jaredi,
2 Cainã, Malaleel, Jared,
3 Enoku, Metusela, Lameki,
3 Henoc, Matusalém,Lamec,
4 Àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
4 Noé, Sem, Cam e Jafet.
5 Àwọn ọmọ Jafeti ni:
5 Filhos de Jafet: Gomer, Magog, Madai, Javã, Tubal, Mosoc e Tiras.
6 Àwọn ọmọ Gomeri ni:
6 Filhos de Gomer: Asquenaz, Rifiat, e Togorma.
7 Àwọn ọmọ Jafani ni:
7 Filhos de Javã: Elisa, Tarsis, Cetim e Dodanim.
8 Àwọn ọmọ Hamu ni:
8 Filhos de Cam: Cus, Mesraim, Fut, e Canaã.
9 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:
9 Filhos de Cus: Saba, Hevila, Sabata, Regma e Sabteca. Filhos de Regma: Saba e Dadã.
10 Kuṣi sì bí Nimrodu
10 Cus gerou Nemrod, aquele que por primeiro foi poderoso na terra.
11 Ejibiti sì bí
11 Mesraim gerou os ludim, os ananim, os laabim, os neftuim, os fetrusim, os casluim,
12 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
12 dos quais procederam os filisteus e os caftorim.
13 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀,
13 Canaã gerou Sidon, seu primogênito, e Het,
14 àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
14 os jebuseus, os amorreus e os gergeseus,
15 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
15 os heveus, os araceus, os sineus,
16 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
16 os aradeus, os samareus e os hamateus.
17 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:
17 Filhos de Sem: Elão, Assur, Arfaxad, Lud, Arão, Hus, Hul, Geter, e Mosoc.
18 Arfakṣadi sì bí Ṣela,
18 Arfaxad gerou Sale, o qual gerou Heber.
19 Eberi sì bí ọmọ méjì:
19 Dois filhos nasceram a Heber: um se chamou Faleg, porque a divisão da terra foi em seu tempo, e seu irmão foi chamado Jectã.
20 Joktani sì bí
20 Jectã gerou Elmodad, Salef, Asarmot,
21 Hadoramu, Usali, Dikla,
21 Jaré, Adorão, Huzal e Decla;
22 Ebali, Abimaeli, Ṣeba.
22 Hebal, Abimael, Seba,
23 Ofiri, Hafila, àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
23 Ofir, Hevila e Jobab, todos filhos de Jectã.
24 Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,
24 De Sem: Arfaxad, Sale,
25 Eberi, Pelegi. Reu,
25 Heber, Faleg, Ragau,
26 Serugu, Nahori, Tẹra,
26 Serug, Nacor, Taré,
27 àti Abramu (tí ń ṣe Abrahamu).
27 Abrão, que é Abraão.
28 Àwọn ọmọ Abrahamu: Isaaki àti Iṣmaeli.
28 Filhos de Abraão: Isaac e Ismael,
29 Èyí ni àwọn ọmọ náà:
29 dos quais a posteridade é a seguinte: Nabaiot, primogênito de Ismael; em seguida, Cedar, Adbeel, Mabsão,
30 Miṣima, Duma, Massa, Hadadi, Tema,
30 Masma, Duma, Massa, Hadad, Tema,
31 Jeturi, Nafiṣi, àti Kedema.
31 Jetur, Nafis, Cedma, que são os filhos de Ismael.
32 Àwọn ọmọ Ketura, obìnrin Abrahamu:
32 Filhos de Cetura, concubina de Abraão: ela deu à luz Zimrã, Jecsã, Madã, Madiã, Jesboc e Sué. Filhos de Jecsã: Seba e Dedã.
33 Àwọn ọmọ Midiani:
33 Filhos de Madiã: Efa, Efer, Henoc, Abida e Eldaa, todos filhos de Cetura.
34 Abrahamu sì jẹ́ baba Isaaki.
34 Abraão gerou Isaac. Filhos de Isaac: Esaú e Jacó.
35 Àwọn ọmọ Esau:
35 Filhos de Esaú: Elifaz, Rauel, Jeus, Ielon e Coré.
36 Àwọn ọmọ Elifasi:
36 Filhos de Elifaz: Temã, Omar, Sef, Gatã, Cenez, Tamna, Amalec.
37 Àwọn ọmọ Reueli:
37 Filhos de Rauel: Naat, Zara, Sama e Meza.
38 Àwọn ọmọ Seiri:
38 Filhos de Seir: Lotã, Sobal, Sebeon, Ana, Dison, Eser e Disã.
39 Àwọn ọmọ Lotani:
39 Filhos de Lotã: Hori e Homão. Irmã de Lotã: Tamna.
40 Àwọn ọmọ Ṣobali:
40 Filhos de Sobal: Aliã, Manaat, Ebal, Sefi e Onão. Filhos de Sebeon: Aia e Ana. Filho de Ana: Dison.
41 Àwọn ọmọ Ana:
41 Filhos de Dison: Hamrão, Esebã, Jetrã e Carã.
42 Àwọn ọmọ Eseri:
42 Filhos de Eser: Balaa, Zavã e Jacã. Filhos de Disã: Hus e Arã.
43 Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu, kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli:
43 Eis os reis que reinaram na terra de Edom, antes que um rei governasse sobre os israelitas. Bela, filho de Beor, cuja cidade se chamava Denaba.
44 Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
44 Depois da morte de Bela, Jobab, filho de Zaré, de Bosra, reinou em seu lugar.
45 Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
45 Jobab morreu e Husão, do país dos temanitas, lhe sucedeu.
46 Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.
46 Estando Husão morto, subiu ao trono Adad, filho de Badad, que derrotou os madianitas na terra de Moab. Sua cidade se chamava Avit.
47 Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
47 Adad morreu, e Semla, de Masreca, lhe sucedeu.
48 Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
48 Semla morreu, e Saul de Roobot, que está situado junto do rio, lhe sucedeu.
49 Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani, ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
49 Saul morreu e Balanã, filho de Acobor, lhe sucedeu.
50 Nígbà tí Baali-Hanani kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.
50 Balanã morreu, e Adad lhe sucedeu. Sua cidade se chamava Fau, e sua mulher Meetabel, filha de Matred, filha de Mesaab.
51 Hadadi sì kú pẹ̀lú.
51 Morreu Adad. Os governadores de Edom foram: o governador de Tamna, o governador Alva, o governador Jetet,
52 baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni.
52 o governador Oolibama, o governador Ela, o governador Finon,
53 Baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,
53 o governador Cenez, o governador Temã, o governador Mabsar,
54 Magdieli àti Iramu.
54 o governador Magdiel, o governador Hirão. Estes são os governadores de Edom.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 1, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.