1 Crônicas 1
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARIB
1 Adamu, Seti, Enoṣi,
1 Adão, Sete, Enos,
2 Kenani, Mahalaleli, Jaredi,
2 Quenã, Maalalel, Jarede,
3 Enoku, Metusela, Lameki,
3 Enoque, Matusalém, Lameque,
4 Àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
4 Noé, Sem, Cam e Jafé.
5 Àwọn ọmọ Jafeti ni:
5 Os filhos de Jafé: Gomer, Magogue, Madai, Javã, Tubal, Meseque e Tiras.
6 Àwọn ọmọ Gomeri ni:
6 Os filhos de Gomer: Asquenaz, Rifate e Togarma.
7 Àwọn ọmọ Jafani ni:
7 Os filhos de Javã: Elisá, Társis, Quitim e Dodanim.
8 Àwọn ọmọ Hamu ni:
8 Os filhos de Cam: Cuche, Mizraim, Pute e Canaã.
9 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:
9 Os filhos de Cuche: Seba, Havilá, Sabtá, Raamá e Sabtecá; e os filhos de Raamá: Sebá e Dedã.
10 Kuṣi sì bí Nimrodu
10 Cuche foi pai de Ninrode, o qual foi o primeiro a ser poderoso na terra:
11 Ejibiti sì bí
11 De Mizraim descenderam os ludeus, os anameus, os leabeus, os naftueus,
12 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
12 os patrusins, os casluins {dos quais procederam os filisteus} e os caftoreus.
13 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀,
13 Canaã foi pai de Sidom, seu primogênito, e de Hete,
14 àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
14 e dos jebuseus, dos amorreus, dos girgaseus,
15 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
15 dos heveus, dos arqueus, dos sineus,
16 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
16 dos arvadeus, dos zemareus e dos hamateus.
17 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:
17 Os filhos de Sem: Elão, Assur, Arfaxade, Lude, Arã, Uz, Hul, Geter e Meseque.
18 Arfakṣadi sì bí Ṣela,
18 Arfaxade foi pai de Selá; e Selá foi pai de Eber.
19 Eberi sì bí ọmọ méjì:
19 A Eber nasceram dois filhos: o nome dum foi Pelegue, pois nos seus dias se repartiu a terra; e o nome do seu irmão foi Joctã.
20 Joktani sì bí
20 Joctã foi pai de Almodá, Selefe, Hazarmavé, Jerá,
21 Hadoramu, Usali, Dikla,
21 Hadorão, Uzal, Diclá,
22 Ebali, Abimaeli, Ṣeba.
22 Ebal, Abimael, Sebá,
23 Ofiri, Hafila, àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
23 Ofir, Havilá e Jobabe; todos esses foram filhos de Joctã.
24 Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,
24 Sem, Arfaxade, Selá;
25 Eberi, Pelegi. Reu,
25 Eber, Pelegue, Reú;
26 Serugu, Nahori, Tẹra,
26 Serugue, Naor, Tera;
27 àti Abramu (tí ń ṣe Abrahamu).
27 Abrão, que é Abraão.
28 Àwọn ọmọ Abrahamu: Isaaki àti Iṣmaeli.
28 Os filhos de Abraão: Isaque e Ismael.
29 Èyí ni àwọn ọmọ náà:
29 Estas são as suas gerações: o primogênito de Ismael, Nebaiote; depois Quedar, Adbeel, Mibsão,
30 Miṣima, Duma, Massa, Hadadi, Tema,
30 Misma, Dumá, Massá, Hadade, Tema,
31 Jeturi, Nafiṣi, àti Kedema.
31 Jetur, Nafis e Quedemá; esses foram os filhos de Ismael.
32 Àwọn ọmọ Ketura, obìnrin Abrahamu:
32 Quanto aos filhos de Quetura, concubina de Abraão, esta deu à luz Zinrã, Jocsã, Medã, Midiã, Isbaque e Suá. Os filhos de Jocsã foram Sebá e Dedã.
33 Àwọn ọmọ Midiani:
33 Os filhos de Midiã: Efá, Efer, Hanoque, Abidá e Eldá; todos esses foram filhos de Quetura.
34 Abrahamu sì jẹ́ baba Isaaki.
34 Abraão foi pai de Isaque. Os filhos de Isaque: Esaú e Israel.
35 Àwọn ọmọ Esau:
35 Os filhos de Esaú: Elifaz, Reuel, Jeús, Jalão e Corá.
36 Àwọn ọmọ Elifasi:
36 Os filhos de Elifaz: Temã, Omar, Zefi, Gatã, Quenaz, Timna e Amaleque.
37 Àwọn ọmọ Reueli:
37 Os filhos de Reuel: Naate, Zerá, Samá e Mizá.
38 Àwọn ọmọ Seiri:
38 Os filhos de Seir: Lotã, Sobal, Zibeão, Anás, Disom, Eser e Disã.
39 Àwọn ọmọ Lotani:
39 Os filhos de Lotã: Hori, e Homã; e a irmã de Lotã foi Timna.
40 Àwọn ọmọ Ṣobali:
40 Os filhos de Sobal: Aliã, Manaate, Ebal, Sefi e Onã. Os filhos de Zibeão: Aías e Anás.
41 Àwọn ọmọ Ana:
41 Anás foi pai de Disom. Os filhos de Disom: Hanrão, Esbã, Itrã e Querã.
42 Àwọn ọmọ Eseri:
42 Os filhos de Eser: Bilã, Zaavã e Jaacã. Os filhos de Disã: Uz e Arã.
43 Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu, kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli:
43 Estes foram os reis que reinaram na terra de Edom, antes que houvesse rei sobre os filhos de Israel: Belá, filho de Beor; e era o nome da sua cidade Dinabá.
44 Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
44 Morreu Belá, e reinou em seu lugar Jobabe, filho de Zerá, de Bozra.
45 Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
45 Morreu Jobabe, e reinou em seu lugar Husão, da terra dos temanitas.
46 Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.
46 Morreu Husão, e reinou em seu lugar Hadade, filho de Bedade, que derrotou os midianitas no campo de Moabe; e era o nome da sua cidade Avite.
47 Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
47 Morreu Hadade, e reinou em seu lugar Sâmela, de Masreca.
48 Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
48 Morreu Sâmela, e reinou em seu lugar Saul, de Reobote junto ao rio.
49 Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani, ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
49 Morreu Saul, e reinou em seu lugar Baal-Ranã, filho de Acbor.
50 Nígbà tí Baali-Hanani kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.
50 Morreu Baal-Hanã, e Hadade reinou em seu lugar; e era o nome da sua cidade Paí. O nome de sua mulher era Meetabel, filha de Matrede, filha de Me-Zaabe.
51 Hadadi sì kú pẹ̀lú.
51 E morreu Hadade. Os príncipes de Edom foram: o príncipe Timna, o príncipe Aliá, o príncipe Jetete,
52 baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni.
52 o príncipe Aolíbama, o príncipe Elá, o príncipe Pinom,
53 Baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,
53 o príncipe Quenaz, o príncipe Temã, o príncipe Mibzar,
54 Magdieli àti Iramu.
54 o príncipe Magdiel, o príncipe lrã. Estes foram os príncipes de Edom.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 1, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.