1 Crônicas 1

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARA

Sair da comparação
ARA Almeida Revista e Atualizada 1993
1 Adamu, Seti, Enoṣi,
1 Adão, Sete, Enos,
2 Kenani, Mahalaleli, Jaredi,
2 Cainã, Maalalel, Jarede,
3 Enoku, Metusela, Lameki,
3 Enoque, Metusalém, Lameque,
4 Àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti.
4 Noé, Sem, Cam e Jafé.
5 Àwọn ọmọ Jafeti ni:
5 Os filhos de Jafé foram: Gomer, Magogue, Madai, Javã, Tubal, Meseque e Tiras.
6 Àwọn ọmọ Gomeri ni:
6 Os filhos de Gomer: Asquenaz, Rifate e Togarma.
7 Àwọn ọmọ Jafani ni:
7 Os filhos de Javã: Elisá, Társis, Quitim e Rodanim.
8 Àwọn ọmọ Hamu ni:
8 Os filhos de Cam: Cuxe, Mizraim, Pute e Canaã.
9 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:
9 Os filhos de Cuxe: Sebá, Havilá, Sabtá, Raamá e Sabtecá; os filhos de Raamá: Sabá e Dedã.
10 Kuṣi sì bí Nimrodu
10 Cuxe gerou a Ninrode, que começou a ser poderoso na terra.
11 Ejibiti sì bí
11 Mizraim gerou a Ludim, a Anamim, a Leabim, a Naftuim,
12 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
12 a Patrusim, a Casluim (de quem descendem os filisteus) e a Caftorim.
13 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀,
13 Canaã gerou a Sidom, seu primogênito, a Hete,
14 àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
14 aos jebuseus, aos amorreus, aos girgaseus,
15 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
15 aos heveus, aos arqueus, aos sineus,
16 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
16 aos arvadeus, aos zemareus e aos hamateus.
17 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:
17 Os filhos de Sem: Elão, Assur, Arfaxade, Lude, Arã, Uz, Hul, Geter e Meseque.
18 Arfakṣadi sì bí Ṣela,
18 Arfaxade gerou a Selá, e Selá gerou a Héber.
19 Eberi sì bí ọmọ méjì:
19 A Héber nasceram dois filhos: o nome de um foi Pelegue, porquanto, nos seus dias, se repartiu a terra; e o nome de seu irmão era Joctã.
20 Joktani sì bí
20 Joctã gerou a Almodá, a Salefe, a Hazar-Mavé, a Jerá,
21 Hadoramu, Usali, Dikla,
21 a Hadorão, a Uzal, a Dicla,
22 Ebali, Abimaeli, Ṣeba.
22 a Ebal, a Abimael, a Sabá,
23 Ofiri, Hafila, àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
23 a Ofir, a Havilá e a Jobabe; todos estes eram filhos de Joctã.
24 Ṣemu, Arfakṣadi, Ṣela,
24 Sem, Arfaxade, Selá,
25 Eberi, Pelegi. Reu,
25 Héber, Pelegue, Reú,
26 Serugu, Nahori, Tẹra,
26 Serugue, Naor, Tera
27 àti Abramu (tí ń ṣe Abrahamu).
27 e Abrão, que é Abraão.
28 Àwọn ọmọ Abrahamu: Isaaki àti Iṣmaeli.
28 Os filhos de Abraão: Isaque e Ismael.
29 Èyí ni àwọn ọmọ náà:
29 São estas as suas gerações: o primogênito de Ismael foi Nebaiote, depois Quedar, Adbeel, Mibsão,
30 Miṣima, Duma, Massa, Hadadi, Tema,
30 Misma, Dumá, Massá, Hadade, Temá,
31 Jeturi, Nafiṣi, àti Kedema.
31 Jetur, Nafis e Quedemá; estes foram os filhos de Ismael.
32 Àwọn ọmọ Ketura, obìnrin Abrahamu:
32 Quanto aos filhos de Quetura, concubina de Abraão, esta deu à luz a Zinrã, a Jocsã, a Medã, a Midiã, a Isbaque e a Sua. Os filhos de Jocsã: Sabá e Dedã.
33 Àwọn ọmọ Midiani:
33 Os filhos de Midiã: Efa, Éfer, Enoque, Abida e Elda; todos estes foram filhos de Quetura.
34 Abrahamu sì jẹ́ baba Isaaki.
34 Abraão, pois, gerou a Isaque. Os filhos de Isaque: Esaú e Israel.
35 Àwọn ọmọ Esau:
35 Os filhos de Esaú: Elifaz, Reuel, Jeús, Jalão e Coré.
36 Àwọn ọmọ Elifasi:
36 Os filhos de Elifaz: Temã, Omar, Zefi, Gaetã, Quenaz, Timna e Amaleque.
37 Àwọn ọmọ Reueli:
37 Os filhos de Reuel: Naate, Zerá, Samá e Mizá.
38 Àwọn ọmọ Seiri:
38 Os filhos de Seir: Lotã, Sobal, Zibeão, Aná, Diso, Eser e Disã.
39 Àwọn ọmọ Lotani:
39 Os filhos de Lotã: Hori e Homã; e a irmã de Lotã foi Timna.
40 Àwọn ọmọ Ṣobali:
40 Os filhos de Sobal eram Aliã, Manaate, Ebal, Sefô e Onã. Os filhos de Zibeão: Aías e Aná.
41 Àwọn ọmọ Ana:
41 O filho de Aná: Disom. Os filhos de Disom: Hanrão, Esbã, Itrã e Querã.
42 Àwọn ọmọ Eseri:
42 Os filhos de Eser: Bilã, Zaavã e Jaacã. Os filhos de Disã: Uz e Arã.
43 Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Edomu, kí ó tó di pé ọba kankan jẹ lórí Israẹli:
43 São estes os reis que reinaram na terra de Edom, antes que houvesse rei sobre os filhos de Israel: Bela, filho de Beor, e o nome da sua cidade era Dinabá.
44 Nígbà tí Bela kú, Jobabu ọmọ Sera ti Bosra sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
44 Morreu Bela, e em seu lugar reinou Jobabe, filho de Zera, de Bozra.
45 Nígbà tí Jobabu kú, Huṣamu láti ilẹ̀ Temani sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
45 Morreu Jobabe, e em seu lugar reinou Husão, da terra dos temanitas.
46 Nígbà tí Huṣamu kú, Hadadi ọmọ Bedadi tí ó kọlu Midiani ní ìgbẹ́ Moabu, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Afiti.
46 Morreu Husão, e em seu lugar reinou Hadade, filho de Bedade; este feriu a Midiã no campo de Moabe; o nome da sua cidade era Avite.
47 Nígbà tí Hadadi sì kú, Samla láti Masreka, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
47 Morreu Hadade, e em seu lugar reinou Samlá, de Masreca.
48 Samla sì kú, Saulu ti Rehoboti létí odò sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
48 Morreu Samlá, e em seu lugar reinou Saul, de Reobote, junto ao Eufrates.
49 Nígbà tí Saulu kú, Baali-Hanani, ọmọ Akbori jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
49 Morreu Saul, e em seu lugar reinou Baal-Hanã, filho de Acbor.
50 Nígbà tí Baali-Hanani kú, Hadadi ni ó jẹ ọba ní ipò rẹ̀. Orúkọ ìlú rẹ̀ ni Pau; orúkọ ìyàwó sì ni Mehetabeeli ọmọbìnrin Matiredi, ọmọbìnrin Mesahabu.
50 Morreu Baal-Hanã, e em seu lugar reinou Hadade; o nome da sua cidade era Paú, e o de sua mulher era Meetabel, filha de Matrede, filha de Me-Zaabe.
51 Hadadi sì kú pẹ̀lú.
51 Morreu Hadade. São estes os nomes dos príncipes de Edom: o príncipe Timna, o príncipe Alva, o príncipe Jetete,
52 baálẹ̀ Oholibama, baálẹ̀ Ela, baálẹ̀ Pinoni.
52 o príncipe Oolibama, o príncipe Elá, o príncipe Pinom,
53 Baálẹ̀ Kenasi, baálẹ̀ Temani, baálẹ̀ Mibsari,
53 o príncipe Quenaz, o príncipe Temã, o príncipe Mibzar,
54 Magdieli àti Iramu.
54 o príncipe Magdiel, o príncipe Irão; são estes os príncipes de Edom.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 1, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.