Jó 22
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs VC
1 Ìgbà náà ni Elifasi, ará Temani, dáhùn wí pé,
1 Elifaz de Temã tomou a palavra nestes termos:
2 “Ènìyàn lè è ṣe rere fún Ọlọ́run?
2 Pode o homem ser útil a Deus? O sábio só é útil a si mesmo.
3 Ohun ayọ̀ ha ni fún Olódùmarè pé olódodo ni ìwọ?
3 De que serve ao Todo-poderoso que tu sejas justo? Tem ele interesse que teu proceder seja íntegro?
4 “Yóò ha bá ọ wí bí, nítorí ìbẹ̀rù
4 É por causa de tua piedade que ele te pune, e entra contigo em juízo?
5 Ìwà búburú rẹ kò ha tóbi,
5 Não é enorme a tua malícia, e não são inumeráveis as tuas iniqüidades?
6 Nítòótọ́ ìwọ béèrè fún ààbò ni ọwọ́ arákùnrin rẹ láìnídìí,
6 Sem causa tomaste penhores a teus irmãos, despojaste de suas vestes os miseráveis;
7 Ìwọ kò fi omi fún aláàárẹ̀ mu,
7 não davas água ao sedento, recusavas o pão ao esfomeado.
8 Bí ó ṣe ti alágbára nì, òun ni ó ní ilẹ̀,
8 A terra era do mais forte, e o protegido é que nela se estabelecia.
9 Ìwọ ti rán àwọn opó padà lọ ní ọwọ́ òfo,
9 Despedias as viúvas com as mãos vazias, quebravas os braços dos órfãos.
10 Nítorí náà ni ìdẹ̀kùn ṣe yí ọ káàkiri,
10 Eis por que estás cercado de laços, e os terrores súbitos te amedrontam.
11 Èéṣe tí òkùnkùn fi pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tí ìwọ kò fi lè ríran.
11 A luz obscureceu-se; já não vês nada; e o dilúvio águas te engole.
12 “Ọlọ́run kò ha jẹ́ ẹni gíga ọ̀run?
12 Não está Deus nas alturas dos céus? Vê a cabeça das estrelas como está alta!
13 Ìwọ sì wí pé, Ọlọ́run ti ṣe mọ̀?
13 E dizes: Que sabe Deus? Pode ele julgar através da nuvem opaca?
14 Ǹjẹ́ àwọsánmọ̀ tí ó nípọn jẹ ìbora fún un,
14 As nuvens formam um véu que o impede de ver; ele passeia pela abóbada do céu.
15 Ǹjẹ́ ìwọ fẹ́ rin ipa ọ̀nà ìgbàanì tí àwọn
15 Segues, pois, rotas antigas por onde andavam os homens iníquos
16 A ké wọn lulẹ̀ kúrò nínú ayé láìpé ọjọ́ wọn,
16 que foram arrebatados antes do tempo, e cujos fundamentos foram arrastados com as águas,
17 Àwọn ẹni tí ó wí fún Ọlọ́run pé, ‘Lọ kúrò lọ́dọ̀ wa!
17 e que diziam a Deus: Retira-te de nós, que poderia fazer-nos o Todo-poderoso?
18 Síbẹ̀ ó fi ohun rere kún ilé wọn!
18 Foi ele, entretanto, que lhes cumulou de bens as casas; - longe de mim os conselhos dos maus! -
19 Àwọn olódodo rí ìparun wọn, wọ́n sì yọ̀,
19 Vendo-os, os justos se alegram, e o inocente zomba deles:
20 ‘Lóòtítọ́ àwọn ọ̀tá wa ni a ké kúrò,
20 Nossos inimigos estão aniquilados, e o fogo devorou-lhes as riquezas!
21 “Fa ara rẹ súnmọ́ Ọlọ́run, ìwọ ó sì rí àlàáfíà;
21 Reconcilia-te, pois, com {Deus} e faz as pazes com ele, é assim que te será de novo dada a felicidade;
22 Èmi bẹ̀ ọ́, gba òfin láti ẹnu rẹ̀ wá,
22 aceita a instrução de sua boca, e põe suas palavras em teu coração.
23 Bí ìwọ bá yípadà sọ́dọ̀ Olódùmarè, a sì gbé ọ ró.
23 Se te voltares humildemente para o Todo-poderoso, se afastares a iniqüidade de tua tenda,
24 tí ìwọ bá tẹ́ wúrà dáradára sílẹ̀,
24 se atirares as barras de ouro ao pó, e o ouro de Ofir entre os pedregulhos da torrente,
25 nígbà náà ní Olódùmarè yóò jẹ́ wúrà rẹ,
25 o Todo-poderoso será teu ouro e um monte de prata para ti.
26 Lóòtítọ́ nígbà náà ní ìwọ ó ní inú dídùn nínú Olódùmarè,
26 Então farás do Todo-poderoso as tuas delícias, e levantarás teu rosto a Deus.
27 Bí ìwọ bá gbàdúrà rẹ sọ́dọ̀ rẹ̀, yóò sì gbọ́ tìrẹ,
27 Tu lhe rogarás, e ele te ouvirá, e cumprirás os teus votos:
28 Ìwọ ó sì gbìmọ̀ ohun kan pẹ̀lú, yóò sì fi ìdí múlẹ̀ fún ọ;
28 formarás os teus projetos, que terão feliz êxito, e a luz brilhará em tuas veredas.
29 Nígbà tí ipa ọ̀nà rẹ bá lọ sísàlẹ̀,
29 Pois Deus abaixa o altivo e o orgulhoso, mas socorre aquele que abaixa os olhos.
30 Yóò gba ẹni tí kì í ṣe aláìjẹ̀bi là,
30 Salva o inocente, o qual é libertado pela pureza de suas mãos.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 22, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.