1 Crônicas 6
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs VC
1 Àwọn ọmọ Lefi:
1 Filhos de Levi: Gerson, Caat e Merari.
2 Àwọn ọmọ Kohati:
2 Filhos de Caat: Amrão, Isaar e Oziel.
3 Àwọn ọmọ Amramu:
3 Filhos de Amrão: Aarão, Moisés e Maria. Filhos de Aarão: Nadab, Abiú, Eleazar e Itamar.
4 Eleasari jẹ́ baba Finehasi,
4 Eleazar gerou Finéias e Finéias gerou Abisué,
5 Abiṣua baba Bukki,
5 Abisué gerou Boci, Boci gerou Ozi,
6 Ussi baba Serahiah,
6 Ozi gerou Zaraías, Zaraías gerou Meraiot,
7 Meraioti baba Amariah,
7 Meraiot gerou Amarias, Amarias gerou Aquitob,
8 Ahitubu baba Sadoku,
8 Aquitob gerou Sadoc, Sadoc gerou Aquimaas,
9 Ahimasi baba Asariah,
9 Aquimaas gerou Azarias, Azarias gerou Joanã,
10 Johanani baba Asariah.
10 Joanã gerou Azarias, que exerceu o sacerdócio no templo que Salomão construiu em Jerusalém.
11 Asariah baba Amariah
11 Azarias gerou Amarias, Amarias gerou Aquitob,
12 Ahitubu baba Sadoku.
12 Aquitob gerou Sadoc, Sadoc gerou Selum,
13 Ṣallumu baba Hilkiah,
13 Selum gerou Helcias, Helcias gerou Azarias,
14 Asariah baba Seraiah,
14 Azarias gerou Saraías, Saraías gerou Josedec,
15 A kó Josadaki lẹ́rú nígbà tí Olúwa lé Juda àti Jerusalẹmu kúrò ní ìlú nípasẹ̀ Nebukadnessari.
15 Josedec partiu para o exílio quando o Senhor fez com que Judá e Jerusalém fossem levados ao cativeiro por Nabucodonosor.
16 Àwọn ọmọ Lefi:
16 Filhos de Levi: Gerson, Caat e Merari.
17 Wọ̀nyí ni àwọn orúkọ àwọn ọmọ Gerṣoni:
17 Eis os nomes dos filhos de Gerson: Lobni e Semei.
18 Àwọn ọmọ Kohati:
18 Filhos de Caat: Amrão, Isaar, Hebron e Oziel.
19 Àwọn ọmọ Merari:
19 Filhos de Merari: Mooli e Musi. Eis as famílias de Levi, segundo suas casas patriarcais.
20 Ti Gerṣoni:
20 De Gerson: Lobni, seu filho, Jaat, seu filho, Zama, seu filho,
21 Joah ọmọkùnrin rẹ̀,
21 Joá, seu filho, Ado, seu filho, Zara, seu filho, Jetraim, seu filho.
22 Àwọn ìran ọmọ Kohati:
22 Filhos de Caat: Aminadab, seu filho, Coré, seu filho, Asir,
23 Elkana ọmọkùnrin rẹ̀,
23 seu filho, Elcana, seu filho, Abiasaf, seu filho, Asir,
24 Tahati ọmọkùnrin rẹ̀, Urieli ọmọkùnrin rẹ̀,
24 seu filho, Taat, seu filho, Uriel, seu filho, Ozias, seu filho, Saul, seu filho.
25 Àwọn ìran ọmọ Elkana:
25 Filhos de Elcana: Amasaí e Aquimot,
26 Elkana ọmọ rẹ̀, Sofai ọmọ rẹ̀
26 Elcana, seu filho, Sofaí, seu filho, Naat, seu filho,
27 Eliabu ọmọ rẹ̀,
27 Eliaba, seu filho, Jeroão, seu filho, Elcana, seu filho.
28 Àwọn ọmọ Samuẹli:
28 Os filhos de Samuel: o primogênito Vasseni e Abia.
29 Àwọn ìran ọmọ Merari:
29 Filhos de Merari: Mooli, Lobni, seu filho, Semei, seu filho, Oza, seu filho,
30 Ṣimea ọmọ rẹ̀, Haggiah ọmọ rẹ̀
30 Samaa, seu filho, Hagia, seu filho, Asaia, seu filho.
31 Èyí ní àwọn ọkùnrin Dafidi tí a fi sí ìdí orin nínú ilé Olúwa lẹ́yìn tí àpótí ẹ̀rí ti wá láti sinmi níbẹ̀.
31 Para dirigir o canto na casa do Senhor, depois que a arca foi colocada em lugar de repouso, eis os que Davi escolheu.
32 Wọ́n jíṣẹ́ pẹ̀lú orin níwájú àgọ́ ìpàdé títí tí Solomoni fi kọ́ ilé Olúwa ní Jerusalẹmu. Wọ́n ṣe iṣẹ́ ìsìn wọn ní ìbámu pẹ̀lú ìlànà tí a fi lélẹ̀ fún wọn.
32 Eles cumpriram suas funções de cantores diante do Tabernáculo da Tenda de Reunião até que Salomão construiu o templo do Senhor em Jerusalém. Faziam seu serviço segundo o seu regulamento.
33 Wọ̀nyí ni àwọn ọkùnrin tí ó sìn pẹ̀lú ọmọ wọn.
33 Eis os que cumpriam esse ofício juntamente com seus filhos: Dentre os filhos de Caat: Hemão, cantor, filho de Joel, filho de Samuel,
34 ọmọ Elkana, ọmọ Jerohamu,
34 filho de Elcana, filho de Jeroão, filho de Eliel, filho de Toul,
35 ọmọ Sufu, ọmọ Elkana,
35 filho de Suf, filho de Elcana, filho de Matat, filho de Amasaí,
36 ọmọ Elkana, ọmọ Joẹli,
36 filho de Elcana, filho de Joel, filho de Azarias, filho de Sofonias,
37 ọmọ Tahati, ọmọ Asiri,
37 filho de Taat, filho de Asir, filho de Abiasaf, filho de Coré,
38 ọmọ Isari, ọmọ Kohati,
38 filho de Isaar, filho de Caat, filho de Levi, filho de Israel.
39 Hemani sì darapọ̀ mọ́ Asafu, ẹni tí o sìn ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀:
39 Seu irmão Asaf, que estava à sua direita; Asaf, filho de Baraquias, filho de Samaa,
40 ọmọ Mikaeli, ọmọ Baaseiah,
40 filho de Miguel, filho de Basaías, filho de Melquias,
41 ọmọ Etini,
41 filho de Atanai, filho de Zara, filho de Adaia,
42 ọmọ Etani, ọmọ Simma,
42 filho de Etã, filho de Zama, filho de Semei,
43 ọmọ Jahati,
43 filho de Jet, filho de Gerson, filho de Levi.
44 láti ìbákẹ́gbẹ́ wọn, àwọn ará Merari wà ní ọwọ́ òsì rẹ̀:
44 Filhos de Merari, seus irmãos, à esquerda: Etã, filho de Cusi, filho de Abdi, filho de Maloc,
45 ọmọ Haṣabiah,
45 filho de Hasabias, filho de Amasias, filho de Helcias,
46 ọmọ Amisi, ọmọ Bani,
46 filho de Amassaí, filho de Boni, filho de Somer,
47 ọmọ Mahili,
47 filho de Mooli, filho de Musi, filho de Merari, filho de Levi.
48 Àwọn Lefi ẹgbẹ́ wọn ni wọn yan àwọn iṣẹ́ yòókù ti àgọ́ fún, èyí tí í ṣe ilé Ọlọ́run.
48 Seus irmãos levitas estavam encarregados de todo o serviço do Tabernáculo da casa do Senhor.
49 Ṣùgbọ́n Aaroni àti àwọn ìran ọmọ rẹ̀ jẹ́ àwọn tí ó gbé ọrẹ kalẹ̀ lórí pẹpẹ ẹbọ sísun àti lórí pẹpẹ tùràrí ní ìbátan pẹ̀lú gbogbo ohun tí a ṣe ní Ibi Mímọ́ Jùlọ. Ṣíṣe ètùtù fún Israẹli, ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run ti pàṣẹ.
49 Aarão e seus filhos queimavam as oblações no altar dos holocaustos e no altar dos perfumes. Eles tomavam sobre si todo o serviço do Santo dos Santos, e faziam a expiação por Israel, segundo as prescrições de Moisés, servo de Deus.
50 Wọ̀nyí ni àwọn ìránṣẹ́ Aaroni:
50 Eis os filhos de Aarão: Eleazar, seu filho, Finéias, seu filho, Abisué, seu filho,
51 Bukki ọmọ rẹ̀,
51 Boci, seu filho, Ozi, seu filho, Zaraías,
52 Meraioti ọmọ rẹ̀, Amariah ọmọ rẹ̀,
52 seu filho, Meraiot, seu filho, Amarias, seu filho, Aquitob,
53 Sadoku ọmọ rẹ̀
53 seu filho, Sadoc, seu filho, Aquimaas, seu filho.
54 Wọ̀nyí ni ibùgbé wọn tí a pín fún wọn gẹ́gẹ́ bí agbègbè wọn (tí a fi lé àwọn ìran ọmọ Aaroni lọ́wọ́ tí ó wá láti ẹ̀yà Kohati, nítorí kèké alákọ́kọ́ jẹ́ tiwọn).
54 Eles se estabeleceram nos territórios das seguintes cidades. Aos filhos de Aarão, da família dos caatitas,
55 A fún wọn ní Hebroni ní Juda pẹ̀lú àyíká pápá oko tútù ilẹ̀ rẹ̀.
55 que por primeiro a sorte designou, foi dada Hebron e suas redondezas na terra de Judá.
56 Ṣùgbọ́n àwọn pápá àti ìletò tí ó yí ìlú ńlá náà ká ni a fi fún Kalebu ọmọ Jefunne.
56 Mas foi dado a Caleb, filho de Jefoné, o território da cidade e suas aldeias.
57 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìran ọmọ Aaroni ni a fún ní Hebroni (ìlú ti ààbò), àti Libina, Jattiri, Eṣitemoa,
57 Foi, portanto, dada aos filhos de Aarão, a cidade de refúgio, Hebron, Lobna e seus arredores, Jeter, Estemo e seus arredores,
58 Hileni, Debiri,
58 Helon e seus arredores, Dabir e seus arredores,
59 Aṣani, Jutta àti Beti-Ṣemeṣi lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ rẹ̀.
59 Asã e seus arredores, Betsemes e seus arredores.
60 Àti láti inú ẹ̀yà Benjamini, a fún wọn ní Gibeoni, Geba, Alemeti àti Anatoti lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
60 Da tribo de Benjamim, Gabee e seus arredores, Almat e seus arredores, Anatot e seus arredores. O número total de suas cidades foi de treze, conforme suas famílias.
61 Ìyókù àwọn ìran ọmọ Kohati ní a pín ìlú mẹ́wàá fún láti àwọn ìdílé ní ti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase.
61 Os outros filhos de Caat receberam, pela sorte, dez cidades das famílias da tribo {de Efraim, de Dã}, e da meia tribo de Manassés.
62 Àwọn ìran ọmọ Gerṣoni, sí ìdílé ni a pín ìlú mẹ́tàlá fún láti ẹ̀yà àwọn ẹ̀yà Isakari, Aṣeri àti Naftali, àti láti apá ẹ̀yà Manase tí ó wà ní Baṣani.
62 Aos filhos de Gerson, segundo suas famílias, foram dadas treze cidades da tribo de Issacar, de Aser, de Neftali e de Manassés em Basã.
63 Sebuluni àwọn ìran ọmọ Merari, ìdílé sí ìdílé, ní a pín ìlú méjìlá fún láti ẹ̀yà Reubeni, Gadi àti Sebuluni.
63 Aos filhos de Merari, segundo suas famílias, foram dadas, pela sorte, doze cidades das tribos de Rubem, de Gad, e de Zabulon.
64 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli fún àwọn ará Lefi ní ìlú wọ̀nyí pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
64 Os israelitas deram aos levitas essas cidades e suas pastagens.
65 Láti ẹ̀yà Juda, Simeoni àti Benjamini ni a pín ìlú tí a ti dárúkọ wọn sẹ́yìn fún.
65 Da tribo dos filhos de Judá, de Simeão, e de Benjamim, foram essas, designadas por seus nomes, as cidades que lhes foram dadas, por meio da sorte.
66 Lára àwọn ìdílé Kohati ni a fún ní ìlú láti ẹ̀yà Efraimu gẹ́gẹ́ bí ìlú agbègbè wọn.
66 Quanto às famílias dos filhos de Caat, as cidades que lhes couberam eram da tribo de Efraim.
67 Ní òkè orílẹ̀-èdè Efraimu, a fún wọn ní Ṣekemu (ìlú ńlá ti ààbò), àti Geseri
67 Foram-lhes dadas as cidades de refúgio, Siquém, e suas redondezas na montanha de Efraim, Gazer e seus arredores,
68 Jokimeamu, Beti-Horoni.
68 Jecmaã e seus arredores, Betoron e seus arredores,
69 Aijaloni àti Gati-Rimoni lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
69 Helon e seus arredores, Getremon e seus arredores;
70 Pẹ̀lú láti apá ààbọ̀ ẹ̀yà Manase àwọn ọmọ Israẹli fún Aneri àti Bileamu lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn, fún ìyókù àwọn ìdílé Kohati.
70 e, da meia tribo de Manassés, Aner e seus arredores, Balaão e seus arredores. É o que foi dado às famílias dos outros filhos de Caat.
71 Àwọn ará Gerṣoni gbà nǹkan wọ̀nyí.
71 Aos filhos de Gerson foram dadas, na meia tribo de Manassés, Gaulon em Basã e seus arredores, Astarot e seus arredores;
72 Láti ẹ̀yà Isakari wọ́n gba Kedeṣi, Daberati
72 da tribo de Issacar, Cedes e seus arredores, Daberet e seus arredores,
73 Ramoti àti Anenu, lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
73 Ramot e seus arredores, Anem e seus arredores;
74 Láti ẹ̀yà Aṣeri wọ́n gba Maṣali, Abdoni,
74 da tribo de Aser, Masal e seus arredores, Abdon e seus arredores,
75 Hukoki àti Rehobu lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
75 Hucac e seus arredores, Roob e seus arredores;
76 Pẹ̀lú láti ẹ̀yà Naftali wọ́n gba Kedeṣi ní Galili, Hammoni àti Kiriataimu, lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
76 da tribo de Neftali, Cedes na Galiléia e seus arredores, Hamon e seus arredores e Cariataim e seus arredores.
77 Àwọn ará Merari (ìyókù àwọn ará Lefi) gbà nǹkan wọ̀nyí.
77 Aos outros filhos de Merari foram dadas, da tribo de Zabulon, Remono e seus arredores, Tabor e seus arredores;
78 Láti ẹ̀yà Reubeni rékọjá Jordani ìlà-oòrùn Jeriko wọ́n gba Beseri nínú aginjù Jahisa,
78 do outro lado do Jordão, de Jericó ao oriente, da tribo de Rubem, Bosor no deserto e seus arredores, Jassa e seus arredores,
79 Kedemoti àti Mefaati, lápapọ̀ pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.
79 Cademot e seus arredores, Mefaat e seus arredores;
80 Pẹ̀lú láti ẹ̀yà Gadi wọ́n gba Ramoti ní Gileadi Mahanaimu,
80 da tribo de Gad, Ramot em Galaad e seus arredores, Manaim e seus arredores,
81 Heṣboni àti Jaseri lápapọ̀ pẹ̀lú àwọn ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.
81 Hesebon e seus arredores, Jeser e seus arredores.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 6, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.