1 Crônicas 6

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NVI

Sair da comparação
NVI Nova Versão Internacional
1 Àwọn ọmọ Lefi:
1 Estes foram os filhos de Levi: Gérson, Coate e Merari.
2 Àwọn ọmọ Kohati:
2 Estes foram os filhos de Coate: Anrão, Isar, Hebrom e Uziel.
3 Àwọn ọmọ Amramu:
3 Estes foram os filhos de Anrão: Arão, Moisés e Miriã. Estes foram os filhos de Arão: Nadabe, Abiú, Eleazar e Itamar.
4 Eleasari jẹ́ baba Finehasi,
4 Eleazar gerou Finéias, Finéias gerou Abisua,
5 Abiṣua baba Bukki,
5 Abisua gerou Buqui, Buqui gerou Uzi,
6 Ussi baba Serahiah,
6 Uzi gerou Zeraías, Zeraías gerou Meraiote,
7 Meraioti baba Amariah,
7 Meraiote gerou Amarias, Amarias gerou Aitube,
8 Ahitubu baba Sadoku,
8 Aitube gerou Zadoque, Zadoque gerou Aimaás,
9 Ahimasi baba Asariah,
9 Aimaás gerou Azarias, Azarias gerou Joanã,
10 Johanani baba Asariah.
10 Joanã gerou Azarias que foi sacerdote no templo construído por Salomão em Jerusalém;
11 Asariah baba Amariah
11 Azarias gerou Amarias, Amarias gerou Aitube,
12 Ahitubu baba Sadoku.
12 Aitube gerou Zadoque, Zadoque gerou Salum,
13 Ṣallumu baba Hilkiah,
13 Salum gerou Hilquias, Hilquias gerou Azarias,
14 Asariah baba Seraiah,
14 Azarias gerou Seraías, e Seraías gerou Jeozadaque.
15 A kó Josadaki lẹ́rú nígbà tí Olúwa lé Juda àti Jerusalẹmu kúrò ní ìlú nípasẹ̀ Nebukadnessari.
15 Jeozadaque foi levado prisioneiro quando o Senhor enviou Judá e Jerusalém para o exílio por meio de Nabucodonosor.
16 Àwọn ọmọ Lefi:
16 Estes foram os filhos de Levi: Gérson, Coate e Merari.
17 Wọ̀nyí ni àwọn orúkọ àwọn ọmọ Gerṣoni:
17 Estes são os nomes dos filhos de Gérson: Libni e Simei.
18 Àwọn ọmọ Kohati:
18 Estes foram os filhos de Coate: Anrão, Isar, Hebrom e Uziel.
19 Àwọn ọmọ Merari:
19 Estes foram os filhos de Merari: Mali e Musi. Estes são os clãs dos levitas alistados de acordo com os seus antepassados:
20 Ti Gerṣoni:
20 De Gérson: Seu filho Libni, que foi o pai de Jaate, pai de Zima,
21 Joah ọmọkùnrin rẹ̀,
21 que foi o pai de Joá, pai de Ido, pai de Zerá, que foi o pai de Jeaterai.
22 Àwọn ìran ọmọ Kohati:
22 De Coate: Seu filho Aminadabe, pai de Corá, que foi o pai de Assir,
23 Elkana ọmọkùnrin rẹ̀,
23 pai de Elcana, pai de Ebiasafe, que foi o pai de Assir,
24 Tahati ọmọkùnrin rẹ̀, Urieli ọmọkùnrin rẹ̀,
24 pai de Taate, pai de Uriel, pai de Uzias, que foi o pai de Saul.
25 Àwọn ìran ọmọ Elkana:
25 De Elcana: Amasai, Aimote
26 Elkana ọmọ rẹ̀, Sofai ọmọ rẹ̀
26 e Elcana, pai de Zofai, pai de Naate,
27 Eliabu ọmọ rẹ̀,
27 que foi o pai de Eliabe, pai de Jeroão, pai de Elcana, que foi o pai de Samuel.
28 Àwọn ọmọ Samuẹli:
28 De Samuel: Joel, o mais velho, e Abias, o segundo.
29 Àwọn ìran ọmọ Merari:
29 De Merari: Mali, pai de Libni, pai de Simei, que foi o pai de Uzá,
30 Ṣimea ọmọ rẹ̀, Haggiah ọmọ rẹ̀
30 pai de Siméia, pai de Hagias, que foi o pai de Asaías.
31 Èyí ní àwọn ọkùnrin Dafidi tí a fi sí ìdí orin nínú ilé Olúwa lẹ́yìn tí àpótí ẹ̀rí ti wá láti sinmi níbẹ̀.
31 Estes são os homens a quem Davi encarregou de dirigir os cânticos no templo do Senhor depois que a arca foi levada para lá.
32 Wọ́n jíṣẹ́ pẹ̀lú orin níwájú àgọ́ ìpàdé títí tí Solomoni fi kọ́ ilé Olúwa ní Jerusalẹmu. Wọ́n ṣe iṣẹ́ ìsìn wọn ní ìbámu pẹ̀lú ìlànà tí a fi lélẹ̀ fún wọn.
32 Eles ministravam o louvor diante do tabernáculo, da Tenda do Encontro, até quando Salomão construiu o templo do Senhor em Jerusalém. Eles exerciam suas funções de acordo com as normas estabelecidas.
33 Wọ̀nyí ni àwọn ọkùnrin tí ó sìn pẹ̀lú ọmọ wọn.
33 Estes são os que ministravam, junto com seus filhos: Dentre os coatitas: O músico Hemã, filho de Joel, filho de Samuel,
34 ọmọ Elkana, ọmọ Jerohamu,
34 filho de Elcana, filho de Jeroão, filho de Eliel, filho de Toá,
35 ọmọ Sufu, ọmọ Elkana,
35 filho de Zufe, filho de Elcana, filho de Maate, filho de Amasai,
36 ọmọ Elkana, ọmọ Joẹli,
36 filho de Elcana, filho de Joel, filho de Azarias, filho de Sofonias
37 ọmọ Tahati, ọmọ Asiri,
37 filho de Taate, filho de Assir, filho de Ebiasafe, filho de Corá,
38 ọmọ Isari, ọmọ Kohati,
38 filho de Isar, filho de Coate, filho de Levi, filho de Israel.
39 Hemani sì darapọ̀ mọ́ Asafu, ẹni tí o sìn ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀:
39 À direita de Hemã, ficava seu parente Asafe, filho de Berequias, filho de Siméia,
40 ọmọ Mikaeli, ọmọ Baaseiah,
40 filho de Micael, filho de Baaséias, filho de Malquias,
41 ọmọ Etini,
41 filho de Etni, filho de Zerá, filho de Adaías,
42 ọmọ Etani, ọmọ Simma,
42 filho de Etã, filho de Zima, filho de Simei,
43 ọmọ Jahati,
43 filho de Jaate, filho de Gérson, filho de Levi.
44 láti ìbákẹ́gbẹ́ wọn, àwọn ará Merari wà ní ọwọ́ òsì rẹ̀:
44 Dentre os meraritas: À esquerda de Hemã, parente dos meraritas, ficava Etã, filho de Quisi, filho de Abdi, filho de Maluque,
45 ọmọ Haṣabiah,
45 filho de Hasabias, filho de Amazias, filho de Hilquias,
46 ọmọ Amisi, ọmọ Bani,
46 filho de Anzi, filho de Bani, filho de Sêmer,
47 ọmọ Mahili,
47 filho de Mali, filho de Musi, filho de Merari, filho de Levi.
48 Àwọn Lefi ẹgbẹ́ wọn ni wọn yan àwọn iṣẹ́ yòókù ti àgọ́ fún, èyí tí í ṣe ilé Ọlọ́run.
48 Seus parentes, os outros levitas, foram encarregados de cuidar de todo o serviço do tabernáculo, o templo de Deus.
49 Ṣùgbọ́n Aaroni àti àwọn ìran ọmọ rẹ̀ jẹ́ àwọn tí ó gbé ọrẹ kalẹ̀ lórí pẹpẹ ẹbọ sísun àti lórí pẹpẹ tùràrí ní ìbátan pẹ̀lú gbogbo ohun tí a ṣe ní Ibi Mímọ́ Jùlọ. Ṣíṣe ètùtù fún Israẹli, ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run ti pàṣẹ.
49 Mas era Arão e seus descendentes que cuidavam dos sacrifícios no altar do holocausto e das ofertas no altar de incenso e de todo o serviço do Lugar Santíssimo, e dos sacrifícios de propiciação por Israel, conforme tudo o que Moisés, servo de Deus, tinha ordenado.
50 Wọ̀nyí ni àwọn ìránṣẹ́ Aaroni:
50 Estes foram os descendentes de Arão: o seu filho Eleazar, pai de Finéias, que foi o pai de Abisua,
51 Bukki ọmọ rẹ̀,
51 pai de Buqui, pai de Uzi, que foi o pai de Zeraías,
52 Meraioti ọmọ rẹ̀, Amariah ọmọ rẹ̀,
52 pai de Meraiote, pai de Amarias, que foi o pai de Aitube,
53 Sadoku ọmọ rẹ̀
53 pai de Zadoque, pai de Aimaás.
54 Wọ̀nyí ni ibùgbé wọn tí a pín fún wọn gẹ́gẹ́ bí agbègbè wọn (tí a fi lé àwọn ìran ọmọ Aaroni lọ́wọ́ tí ó wá láti ẹ̀yà Kohati, nítorí kèké alákọ́kọ́ jẹ́ tiwọn).
54 Estas foram as cidades e as regiões dadas aos levitas para nelas habitarem. Dentre os descendentes de Arão, o clã coatita foi sorteado primeiro;
55 A fún wọn ní Hebroni ní Juda pẹ̀lú àyíká pápá oko tútù ilẹ̀ rẹ̀.
55 foi-lhe dada Hebrom, em Judá, com suas pastagens ao redor.
56 Ṣùgbọ́n àwọn pápá àti ìletò tí ó yí ìlú ńlá náà ká ni a fi fún Kalebu ọmọ Jefunne.
56 Mas os campos e os povoados em torno da cidade foram dados a Calebe, filho de Jefoné.
57 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìran ọmọ Aaroni ni a fún ní Hebroni (ìlú ti ààbò), àti Libina, Jattiri, Eṣitemoa,
57 Assim os descendentes de Arão receberam Hebrom, cidade de refúgio, e Libna, Jatir, Estemoa,
58 Hileni, Debiri,
58 Hilém, Debir,
59 Aṣani, Jutta àti Beti-Ṣemeṣi lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ rẹ̀.
59 Asã, Jutá e Bete-Semes, com suas respectivas pastagens.
60 Àti láti inú ẹ̀yà Benjamini, a fún wọn ní Gibeoni, Geba, Alemeti àti Anatoti lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
60 E da tribo de Benjamim receberam Gibeão, Geba, Alemete e Anatote, com suas respectivas pastagens. Ao todo treze cidades foram distribuídas entre os seus clãs.
61 Ìyókù àwọn ìran ọmọ Kohati ní a pín ìlú mẹ́wàá fún láti àwọn ìdílé ní ti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase.
61 Para os demais descendentes de Coate foram sorteadas dez cidades pertencentes aos clãs da metade da tribo de Manassés.
62 Àwọn ìran ọmọ Gerṣoni, sí ìdílé ni a pín ìlú mẹ́tàlá fún láti ẹ̀yà àwọn ẹ̀yà Isakari, Aṣeri àti Naftali, àti láti apá ẹ̀yà Manase tí ó wà ní Baṣani.
62 Para os descendentes de Gérson, clã por clã, foram sorteadas treze cidades das tribos de Issacar, de Aser e de Naftali, e da metade da tribo de Manassés que fica em Basã.
63 Sebuluni àwọn ìran ọmọ Merari, ìdílé sí ìdílé, ní a pín ìlú méjìlá fún láti ẹ̀yà Reubeni, Gadi àti Sebuluni.
63 Para os descendentes de Merari, clã por clã, foram sorteadas doze cidades das tribos de Rúben, de Gade e de Zebulom.
64 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli fún àwọn ará Lefi ní ìlú wọ̀nyí pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
64 Assim os israelitas deram aos levitas essas cidades com suas respectivas pastagens.
65 Láti ẹ̀yà Juda, Simeoni àti Benjamini ni a pín ìlú tí a ti dárúkọ wọn sẹ́yìn fún.
65 As cidades anteriormente mencionadas dos territórios de Judá, de Simeão e de Benjamim também lhes foram dadas por sorteio.
66 Lára àwọn ìdílé Kohati ni a fún ní ìlú láti ẹ̀yà Efraimu gẹ́gẹ́ bí ìlú agbègbè wọn.
66 Alguns dos clãs coatitas receberam as seguintes cidades no território da tribo de Efraim:
67 Ní òkè orílẹ̀-èdè Efraimu, a fún wọn ní Ṣekemu (ìlú ńlá ti ààbò), àti Geseri
67 Siquém, cidade de refúgio, nos montes de Efraim, e Gezer,
68 Jokimeamu, Beti-Horoni.
68 Jocmeão, Bete-Horom,
69 Aijaloni àti Gati-Rimoni lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
69 Aijalom e Gate-Rimom, com suas respectivas pastagens.
70 Pẹ̀lú láti apá ààbọ̀ ẹ̀yà Manase àwọn ọmọ Israẹli fún Aneri àti Bileamu lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn, fún ìyókù àwọn ìdílé Kohati.
70 E da metade da tribo de Manassés o restante dos clãs coatitas recebeu Aner e Bileã, com suas respectivas pastagens.
71 Àwọn ará Gerṣoni gbà nǹkan wọ̀nyí.
71 Os gersonitas receberam as seguintes cidades: Do clã da meia tribo de Manassés, Golã, em Basã, e também Asterote, com suas respectivas pastagens;
72 Láti ẹ̀yà Isakari wọ́n gba Kedeṣi, Daberati
72 da tribo de Issacar, Quedes, Daberate,
73 Ramoti àti Anenu, lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
73 Ramote e Aném, com suas respectivas pastagens;
74 Láti ẹ̀yà Aṣeri wọ́n gba Maṣali, Abdoni,
74 da tribo de Aser, Masal, Abdom,
75 Hukoki àti Rehobu lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
75 Hucoque e Reobe, com suas respectivas pastagens;
76 Pẹ̀lú láti ẹ̀yà Naftali wọ́n gba Kedeṣi ní Galili, Hammoni àti Kiriataimu, lápapọ̀ pẹ̀lú pápá oko tútù ilẹ̀ wọn.
76 e da tribo de Naftali, Quedes, na Galiléia, Hamom e Quiriataim, com suas respectivas pastagens.
77 Àwọn ará Merari (ìyókù àwọn ará Lefi) gbà nǹkan wọ̀nyí.
77 E estas foram as cidades que os outros meraritas receberam: Da tribo de Zebulom, Rimono e Tabor, com suas respectivas pastagens;
78 Láti ẹ̀yà Reubeni rékọjá Jordani ìlà-oòrùn Jeriko wọ́n gba Beseri nínú aginjù Jahisa,
78 da tribo de Rúben, do outro lado do Jordão, a leste de Jericó, Bezer, no deserto, Jaza,
79 Kedemoti àti Mefaati, lápapọ̀ pẹ̀lú ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.
79 Quedemote e Mefaate, com suas respectivas pastagens;
80 Pẹ̀lú láti ẹ̀yà Gadi wọ́n gba Ramoti ní Gileadi Mahanaimu,
80 e da tribo de Gade, Ramote, em Gileade, Maanaim,
81 Heṣboni àti Jaseri lápapọ̀ pẹ̀lú àwọn ilẹ̀ pápá oko tútù wọn.
81 Hesbom e Jazar, com suas respectivas pastagens.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 6, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.