Jó 32
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs VC
1 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọkùnrin mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wọ̀nyí dákẹ́ láti dá Jobu lóhùn, nítorí ó ṣe olódodo lójú ara rẹ̀.
1 Como Jó persistisse em considerar-se como um justo, estes três homens cessaram de lhe responder.
2 Nígbà náà ni inú bí Elihu ọmọ Barakeli ará Busi, láti ìbátan ìdílé Ramu; ó bínú si Jobu nítorí ti ó dá ara rẹ̀ láre kàkà ki ó dá Ọlọ́run láre.
2 Então se inflamou a cólera de Eliú, filho de Baraquel, de Buz, da família de Rão; sua cólera inflamou-se contra Jó, por este pretender justificar-se perante Deus.
3 Inú sì bí i sí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta, nítorí tí wọn kò rí ọ̀nà láti dá Jobu lóhùn bẹ́ẹ̀ ni wọ́n dá Jobu lẹ́bi.
3 Inflamou-se também contra seus três amigos, por não terem achado resposta conveniente, dando assim culpa a Deus.
4 Ǹjẹ́ Elihu ti dúró títí tí Jobu fi sọ̀rọ̀ tán nítorí tí àwọn wọ̀nyí dàgbà ju òun lọ ní ọjọ́ orí.
4 Como fossem mais velhos do que ele, Eliú tinha se abstido de responder a Jó.
5 Nígbà tí Elihu rí i pé ìdáhùn ọ̀rọ̀ kò sí ní ẹnu àwọn ọkùnrin mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wọ̀nyí nígbà náà ni ó bínú.
5 Mas, quando viu que não tinham mais nada para responder, encolerizou-se.
6 Elihu, ọmọ Barakeli, ará Busi, dáhùn ó sì wí pé,
6 Então Eliú, filho de Baraquel, de Buz, tomou a palavra nestes termos: Sou jovem em anos, e vós sois velhos; é por isso que minha timidez me impediu de manifestar-vos o meu saber.
7 Èmi wí pé ọjọ́ orí ni ìbá sọ̀rọ̀,
7 Dizia comigo: A idade vai falar; os muitos anos farão conhecer a sabedoria,
8 Ṣùgbọ́n ẹ̀mí kan ní ó wà nínú ènìyàn
8 mas é o Espírito de Deus no homem, e um sopro do Todo-poderoso que torna inteligente.
9 Ènìyàn ńlá ńlá kì í ṣe ọlọ́gbọ́n,
9 Não são os mais velhos que são sábios, nem os anciãos que discernem o que é justo;
10 “Nítorí náà ní èmí ṣe wí pé, ẹ dẹtí sílẹ̀ sí mi;
10 é por isso que digo: Escutai-me, vou mostrar-vos o que sei.
11 Kíyèsi i, èmí ti dúró de ọ̀rọ̀ yín;
11 Esperei enquanto faláveis, prestei atenção em vossos raciocínios. Enquanto discutíeis,
12 àní, mo fiyèsí yín tinútinú.
12 segui-vos atentamente. Mas ninguém refutou Jó, ninguém respondeu aos seus argumentos.
13 Kí ẹ̀yin kí ó má ṣe wí pé, ‘Àwa wá ọgbọ́n ní àwárí;
13 Não digais: Encontramos a sabedoria; é Deus e não um homem quem nos instrui.
14 Bí òun kò ti sọ̀rọ̀ sí mi,
14 Não foi a mim que dirigiu seus discursos, mas encontrarei outras respostas diferentes das vossas.
15 “Ẹnu sì yà wọ́n, wọn kò sì dáhùn mọ́,
15 Ei-los calados, já não dizem mais nada; faltam-lhes as palavras.
16 Mo sì retí, nítorí wọn kò sì fọhùn, wọ́n dákẹ́ jẹ́ẹ́;
16 Esperei que se calassem, que parassem e cessassem de responder.
17 Bẹ́ẹ̀ ni èmí ó sì dáhùn nípa ti èmi,
17 É a minha vez de responder: vou também mostrar o que sei.
18 Nítorí pé èmi kún fún ọ̀rọ̀ sísọ,
18 Pois estou cheio de palavras, o espírito que está em meu peito me oprime.
19 Kíyèsi i, ikùn mi dàbí ọtí wáìnì, tí kò ní ojú-ìhò;
19 Meu peito é como o vinho arrolhado, como um barril pronto para estourar.
20 Èmí ó sọ, kí ara kí ó le rọ̀ mí,
20 Vou falar, isto me aliviará, abrirei meus lábios para responder.
21 Lóòtítọ́ èmi kì yóò ṣe ojúsàájú sí ẹnìkankan,
21 Não farei acepção de ninguém, não adularei este ou aquele.
22 Nítorí pé èmí kò mọ̀ ọ̀rọ̀ ìpọ́nni í sọ ní ṣíṣe bẹ́ẹ̀,
22 Pois não sei bajular; do contrário, meu Criador logo me levaria.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 32, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.