Jó 24

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 “Ṣe bí ìgbà kò pamọ́ lọ́dọ̀ Olódùmarè fún ìdájọ́?

2 Wọ́n a sún àmì ààlà ilẹ̀,

3 Wọ́n á sì da kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ aláìní baba lọ,

4 Wọ́n á bi aláìní kúrò lójú ọ̀nà,

5 Kíyèsi i, bí i kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó nínú ijù ni àwọn tálákà jáde lọ sí iṣẹ́ wọn,

6 Olúkúlùkù a sì sá ọkà oúnjẹ ẹran rẹ̀ nínú oko,

7 Ní ìhòhò ni wọn máa sùn láìní aṣọ,

8 Ọ̀wààrà òjò òkè ńlá sì pa wọ́n,

9 Wọ́n já ọmọ aláìní baba kúrò ní ẹnu ọmú,

10 Wọ́n rìn kiri ní ìhòhò láìní aṣọ;

11 Àwọn ẹni tí ń fún òróró nínú àgbàlá wọn,

12 Àwọn ènìyàn ń kérora láti ìlú wá,

13 “Àwọn ni ó wà nínú àwọn tí ó ṣọ̀tẹ̀ sí ìmọ́lẹ̀,

14 Apànìyàn a dìde ní àfẹ̀mọ́júmọ́,

15 Ojú alágbèrè pẹ̀lú dúró kí ilẹ̀ ṣú díẹ̀;

16 Ní òkùnkùn wọn á rúnlẹ̀ wọlé,

17 Nítorí pé bí òru dúdú ní òwúrọ̀ fún gbogbo wọn;

18 “Ó yára lọ bí ẹni lójú omi;

19 Gẹ́gẹ́ bi ọ̀dá àti òru ní í mú omi òjò-dídì yọ́,

20 Inú ìbímọ yóò gbàgbé rẹ̀,

21 Ẹni tí o hù ìwà búburú sí àgàn

22 Ọlọ́run fi ipá agbára rẹ̀ fa alágbára,

23 Ọlọ́run sì fi àìléwu fún un,

24 A gbé wọn lékè nígbà díẹ̀, wọ́n kọjá lọ;

25 “Ǹjẹ́, bí kò bá rí bẹ́ẹ̀ nísinsin yìí, ta ni yóò mú mi ní èké,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 24, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.