Jó 25

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Nígbà náà ní Bilidadi, ará Ṣuhi, dáhùn wí pé,

2 “Ìjọba àti ẹ̀rù ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀,

3 Àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ha ní ìyè bí,

4 Èéha ti ṣe tí a ó fi dá ènìyàn láre lọ́dọ̀ Ọlọ́run?

5 Kíyèsi i, òṣùpá kò sì lè tàn ìmọ́lẹ̀,

6 kí a má sọ ènìyàn tí i ṣe ìdin,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 25, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.