1 Crônicas 2

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Israẹli. Reubeni, Simeoni, Lefi, Juda, Isakari, Sebuluni,
1 Estes são os filhos de Israel: Rúben, Simeão, Levi, e Judá, Issacar, e Zebulom,
2 Dani, Josẹfu, Benjamini; Naftali, Gadi: àti Aṣeri.
2 Dã, José, e Benjamim, Naftali, Gade e Aser.
3 Àwọn ọmọ Juda:
3 Os filhos de Judá: Er, e Onã, e Selá; estes três lhe nasceram da filha de Suá, a cananeia. E Er, o primogênito de Judá, foi mau à vista do SENHOR; que o matou.
4 Tamari, aya ọmọbìnrin Juda, ó sì bí Peresi àti Sera sì ní ọmọ márùn-ún ní àpapọ̀.
4 E Tamar, a sua nora, lhe deu à luz Perez e Zerá. E todos os filhos de Judá foram cinco.
5 Àwọn ọmọ Peresi:
5 Os filhos de Perez: Hezrom, e Hamul.
6 Àwọn ọmọ Sera:
6 E os filhos de Zerá: Zinri, e Etã, e Hemã, e Calcol, e Dara; cinco deles ao todo.
7 Àwọn ọmọ Karmi:
7 E o filho de Carmi: Acar, o perturbador de Israel, que transgrediu na coisa amaldiçoada.
8 Àwọn ọmọ Etani:
8 E o filho de Etã: Azarias.
9 Àwọn ọmọ tí a bí fún Hesroni ni:
9 Os filhos de Hezrom, que lhe nasceram: Jerameel, e Rão, e Quelubai.
10 Ramu sì ni baba Amminadabu,
10 E Rão gerou Aminadabe; e Aminadabe gerou Naassom, príncipe dos filhos de Judá;
11 Nahiṣoni sì ni baba Salmoni,
11 e Naassom gerou Salma, e Salma gerou Boaz,
12 Boasi baba Obedi
12 e Boaz gerou Obede, e Obede gerou Jessé.
13 Jese sì ni baba
13 E Jessé gerou o seu primogênito Eliabe; e Abinadabe, o segundo; e Siméia, o terceiro;
14 ẹlẹ́ẹ̀kẹrin Netaneli,
14 Natanael, o quarto; Radai, o quinto;
15 ẹlẹ́ẹ̀kẹfà Osemu
15 Ozém, o sexto; Davi, o sétimo;
16 Àwọn arábìnrin wọn ni Seruiah àti Abigaili.
16 cujas irmãs eram Zeruia, e Abigail. E os filhos de Zeruia: Abisai, e Joabe, e Asael; três.
17 Abigaili ni ìyá Amasa, ẹni tí baba rẹ̀ sì jẹ́ Jeteri ará Iṣmaeli.
17 E Abigail deu à luz a Amasa; e o pai de Amasa foi Jéter, o ismaelita.
18 Kalebu ọmọ Hesroni ní ọmọ láti ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀ Asuba (láti ọ̀dọ̀ Jerioti). Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ rẹ̀:
18 E Calebe, o filho de Hezrom, gerou filhos de Azuba, a sua esposa, e de Jeriote; os filhos dela são estes: Jeser, e Sobabe, e Ardom.
19 Nígbà tí Asuba sì kú, Kalebu sì fẹ́ Efrata ní aya, ẹni tí ó bí Huri fún un.
19 E morreu Azuba e Calebe tomou para si Efrata, a qual deu à luz Hur.
20 Huri ni baba Uri, Uri sì jẹ́ baba Besaleli.
20 E Hur gerou Uri, e Uri gerou Bezalel.
21 Nígbà tí ó yá, Hesroni sì dùbúlẹ̀ pẹ̀lú ọmọbìnrin Makiri baba Gileadi (ó sì ti fẹ́ ní aya láti ìgbà tí ó ti wà ní ẹni ọgọ́ta ọdún) ó sì bí Segubu.
21 E, depois disso, Hezrom, o pai de Gileade, conheceu a filha de Maquir, com quem se casou quando tinha sessenta anos de idade; e ela lhe deu à luz Segube.
22 Segubu sì jẹ́ baba Jairi, ẹni tí ó jẹ́ olùdarí ìlú mẹ́tàlélógún ní ilẹ̀ Gileadi.
22 E Segube gerou Jair, que tinha vinte e três cidades na terra de Gileade.
23 (Ṣùgbọ́n Geṣuri àti Aramu sì fi agbára gba Hafoti-Jairi, àti Kenati pẹ̀lú gbogbo agbègbè rẹ̀ tí wọn tẹ̀dó sí jẹ́ ọgọ́ta ìlú.)
23 E Gesur e Arã tomaram as aldeias de Jair, juntamente com Quenate, e as suas aldeias, a saber, sessenta cidades. Todas estas pertenciam aos filhos de Maquir, o pai de Gileade.
24 Lẹ́yìn tí Hesroni sì kú ni Kalebu Efrata, Abijah ìyàwó rẹ̀ ti Hesroni sì bí Aṣihuri baba Tekoa fún un.
24 E depois da morte de Hezrom em Calebe-Efrata, Abia, a esposa de Hez­rom, deu-lhe à luz Azur, o pai de Tecoa.
25 Ọmọ Jerahmeeli àkọ́bí Hesroni:
25 E os filhos de Jerameel, o primogênito de Hezrom, foram: Rão, o primogênito, e Buna, e Orém, e Ozém, e Aías.
26 Jerahmeeli ní ìyàwó mìíràn, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Atara; ó sì jẹ́ ìyá fún Onamu.
26 Jerameel teve também outra esposa, cujo nome era Atara; ela foi a mãe de Onã.
27 Àwọn ọmọ Ramu àkọ́bí Jerahmeeli:
27 E os filhos de Rão, o primogênito de Jerameel foram: Maaz, e Jamim, e Equer.
28 Àwọn ọmọ Onamu:
28 E os filhos de Onã foram: Samai e Jada. E os filhos de Samai: Nadabe e Abisur.
29 Orúkọ ìyàwó Abiṣuri ni Abihaili ẹni tí ó bí Ahbani àti Molidi.
29 E o nome da esposa de Abisur era Abigail, e ela deu à luz a Abã e a Molide.
30 Àwọn ọmọ Nadabu
30 E os filhos de Nadabe: Selede e Apaim; mas Selede morreu sem filhos.
31 Àwọn ọmọ Appaimu:
31 E o filho de Apaim: Isi. E o filho de Isi: Sesã. E o filho de Sesã: Alai.
32 Àwọn ọmọ Jada, arákùnrin Ṣammai:
32 E os filhos de Jada, o irmão de Samai: Jéter, e Jônatas; e Jéter morreu sem filhos.
33 Àwọn ọmọ Jonatani:
33 E os filhos de Jônatas: Pelete e Zaza. Estes foram os filhos de Jerameel.
34 Ṣeṣani kò sì ní ọmọkùnrin àwọn ọmọbìnrin nìkan ni ó ní.
34 Ora, Sesã não teve filhos, mas filhas. E Sesã teve um servo egípcio, cujo nome era Jara.
35 Ṣeṣani sì fi ọmọ obìnrin rẹ̀ ní aya fún ìránṣẹ́ rẹ̀ Jariha, ó sì bí ọmọ fún tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ Attai.
35 E Sesã deu a sua filha para Jara, o seu servo, como esposa; e ela deu à luz Atai.
36 Attai sì jẹ́ baba fún Natani,
36 E Atai gerou Natã, e Natã gerou Zabade.
37 Sabadi ni baba Eflali,
37 E Zabade gerou Eflal, e Eflal gerou Obede.
38 Obedi sì ni baba Jehu,
38 E Obede gerou Jeú, e Jeú gerou Azarias.
39 Asariah sì ni baba Helesi,
39 E Azarias gerou Heles, e Heles gerou Eleasa.
40 Eleasa ni baba Sismai,
40 E Eleasa gerou Sismai, e Sismai gerou Salum.
41 Ṣallumu sì ni baba Jekamiah,
41 E Salum gerou Jecamias, e Jecamias gerou Elisama.
42 Àwọn ọmọ Kalebu arákùnrin Jerahmeeli:
42 Ora, o filho de Calebe, o irmão de Jerameel foram, Messa, o seu primogênito, o qual foi o pai de Zife; e os filhos de Maressa, o pai de Hebrom.
43 Àwọn ọmọ Hebroni:
43 E os filhos de Hebrom: Coré, e Tapua, e Requém, e Sema.
44 Ṣema ni baba Rahamu,
44 E Sema gerou Raão, o pai de Jorqueão; e Requém gerou Samai.
45 Àwọn ọmọ Ṣammai ni Maoni,
45 E o filho de Samai foi Maom; e Maom foi o pai de Bete-Zur.
46 Efani obìnrin Kalebu sì ni ìyá
46 E Efá, a concubina de Calebe, deu à luz a Harã, e Mosa, e Gazez; e Harã gerou Gazez.
47 Àwọn ọmọ Jahdai:
47 E os filhos de Jadai: Regém, e Jotão e Gesã, e Pelete, e Efá e Saafe.
48 Maaka obìnrin Kalebu sì ni ìyá
48 Maaca, concubina de Calebe, deu à luz a Seber, e Tiraná.
49 Ó sì bí Ṣaafu baba Madmana,
49 Ela deu também à luz Saafe, o pai de Madmana; Seva, o pai de Gibeá; e a filha de Calebe foi Acsa.
50 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Kalebu.
50 Estes foram os filhos de Calebe, o filho de Hur, o primogênito de Efrata: Sobal, o pai de Quiriate-Jearim,
51 Salma baba Bẹtilẹhẹmu àti Harefu baba Beti-Gaderi.
51 Salma, o pai de Belém; Harefe, o pai de Bete-Gader.
52 Àwọn ọmọ Ṣobali baba Kiriati-Jearimu ni:
52 E Sobal, o pai de Quiriate-Jearim, teve filhos: Haroé e a metade dos manaatitas.
53 Àti ìdílé Kiriati-Jearimu: àti àwọn ara Itri, àti àwọn ará Puti, àti àwọn ará Ṣumati àti àwọn ará Miṣraiti: láti ọ̀dọ̀ wọn ni àwọn ọmọ ará Sorati àti àwọn ará Eṣtaoli ti wá.
53 E as famílias de Quiriate-Jearim: os itritas, e os puteus, e os sumateus, e os misraeus; deles vieram os zoratitas, e os estaoleus.
54 Àwọn ọmọ Salma:
54 Os filhos de Salma: Belém, e os netofatitas; Atarote, a casa de Joabe; e a metade dos manassitas, e os zoreus.
55 àti àwọn ìdílé àwọn akọ̀wé, ẹni tí ń gbé ní Jabesi: àti àwọn ọmọ Tirati àti àwọn ará Ṣimeati àti àwọn ará Sukati. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ará Keni, ẹni tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Hamati, baba ilé Rekabu.
55 E as famílias dos escribas que habitaram em Jabez: os tiratitas, os simeatitas, e os sucatitas. Estes são os queneus que vieram de Hamate, o pai da casa de Recabe.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.