1 Crônicas 2
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARIB
1 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Israẹli. Reubeni, Simeoni, Lefi, Juda, Isakari, Sebuluni,
1 Foram estes os filhos de Israel: Rúben, Simeão, Levi, Judá, Issacar, Zebulom,
2 Dani, Josẹfu, Benjamini; Naftali, Gadi: àti Aṣeri.
2 Dã, José, Benjamim, Naftali, Gade e Aser.
3 Àwọn ọmọ Juda:
3 Os filhos de Judá: Er, Onã e Selá; estes três lhe nasceram da filha de Suá, a cananéia. E Er, o primogênito de Judá, foi mau aos olhos do Senhor, que o matou:
4 Tamari, aya ọmọbìnrin Juda, ó sì bí Peresi àti Sera sì ní ọmọ márùn-ún ní àpapọ̀.
4 Tamar, nora de Judá, lhe deu à luz Pérez e Zerá. Ao todo os filhos de Judá foram cinco.
5 Àwọn ọmọ Peresi:
5 Os filhos de Perez: Hezrom e Hamul:
6 Àwọn ọmọ Sera:
6 Os filhos de Zerá: Zinri, Etã, Hemã, Calcol e Dara; cinco ao todo.
7 Àwọn ọmọ Karmi:
7 Os filhos de Carmi: Acar, o perturbador de Israel, que pecou no anátema.
8 Àwọn ọmọ Etani:
8 De Etã foi filho Azarias.
9 Àwọn ọmọ tí a bí fún Hesroni ni:
9 Os filhos que nasceram a Hezrom: Jerameel, Rão e Quelubai.
10 Ramu sì ni baba Amminadabu,
10 Rão foi pai de Aminadabe, e Aminadabe de Nasom, príncipe dos filhos de Judá;
11 Nahiṣoni sì ni baba Salmoni,
11 Nason foi pai de Salmom, e Salmom de Boaz;
12 Boasi baba Obedi
12 Boaz foi pai de Obede, e Obede de Jessé;
13 Jese sì ni baba
13 a Jessé nasceram Eliabe, seu primogênito, Abinadabe o segundo, Siméia o terceiro,
14 ẹlẹ́ẹ̀kẹrin Netaneli,
14 Netanel o quarto, Radai o quinto,
15 ẹlẹ́ẹ̀kẹfà Osemu
15 Ozen o sexto e Davi o sétimo;
16 Àwọn arábìnrin wọn ni Seruiah àti Abigaili.
16 e foram suas irmãs Zeruia e Abigail. Os filhos de Zeruia foram: Abisai, Joabe e Asael, três.
17 Abigaili ni ìyá Amasa, ẹni tí baba rẹ̀ sì jẹ́ Jeteri ará Iṣmaeli.
17 Abigail deu à luz Amasa; o pai de Amasa foi Jeter, o ismaelita.
18 Kalebu ọmọ Hesroni ní ọmọ láti ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀ Asuba (láti ọ̀dọ̀ Jerioti). Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ rẹ̀:
18 A Calebe, filho de Hezrom, nasceram filhos de Azuba, sua mulher, e de Jeriote; e os filhos dela foram estes: Jeser, Sobabe e Ardom.
19 Nígbà tí Asuba sì kú, Kalebu sì fẹ́ Efrata ní aya, ẹni tí ó bí Huri fún un.
19 Morreu Azuba; e Calebe tomou para si Efrata, da qual lhe nasceu Hur.
20 Huri ni baba Uri, Uri sì jẹ́ baba Besaleli.
20 Hur foi pai de îri, e îri de Bezaleel.
21 Nígbà tí ó yá, Hesroni sì dùbúlẹ̀ pẹ̀lú ọmọbìnrin Makiri baba Gileadi (ó sì ti fẹ́ ní aya láti ìgbà tí ó ti wà ní ẹni ọgọ́ta ọdún) ó sì bí Segubu.
21 Então Hezrom, tendo já sessenta anos, tomou por mulher a filha de Maquir, pai de Gileade; e conheceu-a, e ela lhe deu à luz Segube.
22 Segubu sì jẹ́ baba Jairi, ẹni tí ó jẹ́ olùdarí ìlú mẹ́tàlélógún ní ilẹ̀ Gileadi.
22 Segube foi pai de Jair, o qual veio a ter vinte e três cidades na terra de Gileade.
23 (Ṣùgbọ́n Geṣuri àti Aramu sì fi agbára gba Hafoti-Jairi, àti Kenati pẹ̀lú gbogbo agbègbè rẹ̀ tí wọn tẹ̀dó sí jẹ́ ọgọ́ta ìlú.)
23 Mas Gesur e Arã tomaram deles Havote-Jair, e Quenate e suas aldeias, sessenta cidades. Todos estes foram filhos de Maquir, pai de Gileade.
24 Lẹ́yìn tí Hesroni sì kú ni Kalebu Efrata, Abijah ìyàwó rẹ̀ ti Hesroni sì bí Aṣihuri baba Tekoa fún un.
24 Depois da morte de Hezrom, em Calebe de Efrata, Abia, mulher de Hezrom, lhe deu Asur, pai de Tecoa.
25 Ọmọ Jerahmeeli àkọ́bí Hesroni:
25 Os filhos de Jerameel, primogênito de Jezrom, foram: Rão, o primogênito, Buna, Orem, Ozem e Aías.
26 Jerahmeeli ní ìyàwó mìíràn, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Atara; ó sì jẹ́ ìyá fún Onamu.
26 Jerameel teve outra mulher, cujo nome era Atara, a qual foi mãe de Onã.
27 Àwọn ọmọ Ramu àkọ́bí Jerahmeeli:
27 Os filhos de Rão, primogênito de Jerameel, foram: Maaz, Jamim e Equer.
28 Àwọn ọmọ Onamu:
28 Os filhos de Onã, foram: Samai e Jada; e os filhos de Samai: Nadabe e Abisur.
29 Orúkọ ìyàwó Abiṣuri ni Abihaili ẹni tí ó bí Ahbani àti Molidi.
29 O nome da mulher de Abisur era Abiail, que lhe deu à luz Abã e Molide.
30 Àwọn ọmọ Nadabu
30 Os filhos de Nadabe: Selede e Apaim; e Selede morreu sem filhos.
31 Àwọn ọmọ Appaimu:
31 O filho de Apaim: Isi; o filho de Isi: Sesã; o filho de Sesã: Alai.
32 Àwọn ọmọ Jada, arákùnrin Ṣammai:
32 Os filhos de Jada, irmão de Samai: Jeter e Jônatas; e Jeter morreu sem filhos.
33 Àwọn ọmọ Jonatani:
33 Os filhos de Jônatas: Pelete e Zaza. Esses foram os filhos de Jerameel.
34 Ṣeṣani kò sì ní ọmọkùnrin àwọn ọmọbìnrin nìkan ni ó ní.
34 Sesã não teve filhos, mas filhas. E tinha Sesã um servo egípcio, cujo nome era Jará:
35 Ṣeṣani sì fi ọmọ obìnrin rẹ̀ ní aya fún ìránṣẹ́ rẹ̀ Jariha, ó sì bí ọmọ fún tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ Attai.
35 Deu, pois, Sesã sua filha por mulher a Jará, seu servo; e ela lhe deu à luz Atai.
36 Attai sì jẹ́ baba fún Natani,
36 Atai foi pai de Natã, Natã de Zabade,
37 Sabadi ni baba Eflali,
37 Zabade de Eflal, Eflal de Obede,
38 Obedi sì ni baba Jehu,
38 Obede de Jeú, Jeú de Azarias,
39 Asariah sì ni baba Helesi,
39 Azarias de Helez, Helez de Eleasá,
40 Eleasa ni baba Sismai,
40 Eleasá de Sismai, Sismai de Salum,
41 Ṣallumu sì ni baba Jekamiah,
41 Salum de Jecamias, e Jecamias de Elisama.
42 Àwọn ọmọ Kalebu arákùnrin Jerahmeeli:
42 Os filhos de Calebe, irmão de Jerameel: Messa, seu primogênito, que foi o pai de Zife, e os filhos de Maressa, pai de Hebrom.
43 Àwọn ọmọ Hebroni:
43 Os filhos de Hebrom: Corá, Tapua, Requem e Sema.
44 Ṣema ni baba Rahamu,
44 Sema foi pai de Raão, pai de Jorqueão; e Requem foi pai de Samai.
45 Àwọn ọmọ Ṣammai ni Maoni,
45 O filho de Samai foi Maom; e Maom foi pai de Bete-Zur.
46 Efani obìnrin Kalebu sì ni ìyá
46 Efá, a concubina de Calebe, teve Harã, Moza e Gazez; e Harã foi pai de Gazez.
47 Àwọn ọmọ Jahdai:
47 Os filhos de Jadai: Regem, Jotão, Gesã, Pelete, Efá e Saafe.
48 Maaka obìnrin Kalebu sì ni ìyá
48 Maacá, concubina de Calebe, deu à luz Seber e Tiraná.
49 Ó sì bí Ṣaafu baba Madmana,
49 Deu à luz também Saafe, pai de Madmana, e Seva, pai de Macbena e de Gibeá; e a filha de Calebe foi Acsa.
50 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Kalebu.
50 Estes foram os filhos de Calebe, filho de Hur, o primogênito de Efrata: Sobal, pai de Quiriate-Jearim,
51 Salma baba Bẹtilẹhẹmu àti Harefu baba Beti-Gaderi.
51 Salma, pai de Belém, e Harefe, pai de Bete-Gader.
52 Àwọn ọmọ Ṣobali baba Kiriati-Jearimu ni:
52 Os filhos de Sobal, pai de Quiriate-Jearim, foram: Haroé e metade dos menuotes.
53 Àti ìdílé Kiriati-Jearimu: àti àwọn ara Itri, àti àwọn ará Puti, àti àwọn ará Ṣumati àti àwọn ará Miṣraiti: láti ọ̀dọ̀ wọn ni àwọn ọmọ ará Sorati àti àwọn ará Eṣtaoli ti wá.
53 As famílias de Quiriate-Jearim: os itreus, os puteus, os sumateus e os misraeus; destes saíram os zorateus e os estaloeus.
54 Àwọn ọmọ Salma:
54 Os filhos de Salma: Belém, os netofatitas, Atarote-Bete-Joabe, metade dos manaatitas e os zoritas.
55 àti àwọn ìdílé àwọn akọ̀wé, ẹni tí ń gbé ní Jabesi: àti àwọn ọmọ Tirati àti àwọn ará Ṣimeati àti àwọn ará Sukati. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ará Keni, ẹni tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Hamati, baba ilé Rekabu.
55 As famílias dos escribas que habitavam em Jabes: os tiratitas, os simeatitas e os sucatitas; estes são os queneus que descenderam de Hamate, pai da casa de Recabe.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.