1 Crônicas 2
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARA
1 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Israẹli. Reubeni, Simeoni, Lefi, Juda, Isakari, Sebuluni,
1 São estes os filhos de Israel: Rúben, Simeão, Levi, Judá, Issacar, Zebulom,
2 Dani, Josẹfu, Benjamini; Naftali, Gadi: àti Aṣeri.
2 Dã, José, Benjamim, Naftali, Gade e Aser.
3 Àwọn ọmọ Juda:
3 Os filhos de Judá: Er, Onã e Selá; estes três lhe nasceram de Bate-Sua, a cananeia. Er, o primogênito de Judá, foi mau aos olhos do Senhor , pelo que o matou.
4 Tamari, aya ọmọbìnrin Juda, ó sì bí Peresi àti Sera sì ní ọmọ márùn-ún ní àpapọ̀.
4 Porém Tamar, nora de Judá, lhe deu à luz a Perez e a Zera. Todos os filhos de Judá foram cinco.
5 Àwọn ọmọ Peresi:
5 Os filhos de Perez: Hezrom e Hamul.
6 Àwọn ọmọ Sera:
6 Os filhos de Zera: Zinri, Etã, Hemã, Calcol e Dara, cinco ao todo.
7 Àwọn ọmọ Karmi:
7 Os filhos de Carmi: Acar, o perturbador de Israel, que pecou na coisa condenada.
8 Àwọn ọmọ Etani:
8 O filho de Etã: Azarias.
9 Àwọn ọmọ tí a bí fún Hesroni ni:
9 Os filhos de Hezrom, que lhe nasceram: Jerameel, Rão e Quelubai.
10 Ramu sì ni baba Amminadabu,
10 Rão gerou a Aminadabe; Aminadabe gerou a Naassom, príncipe dos filhos de Judá;
11 Nahiṣoni sì ni baba Salmoni,
11 Naassom gerou a Salma, e Salma gerou a Boaz;
12 Boasi baba Obedi
12 Boaz gerou a Obede, e Obede gerou a Jessé;
13 Jese sì ni baba
13 Jessé gerou a Eliabe, seu primogênito, a Abinadabe, o segundo, a Simeia, o terceiro,
14 ẹlẹ́ẹ̀kẹrin Netaneli,
14 a Natanael, o quarto, a Radai, o quinto,
15 ẹlẹ́ẹ̀kẹfà Osemu
15 a Ozém, o sexto, e a Davi, o sétimo.
16 Àwọn arábìnrin wọn ni Seruiah àti Abigaili.
16 As irmãs destes foram Zeruia e Abigail. Os filhos de Zeruia foram três: Abisai, Joabe e Asael.
17 Abigaili ni ìyá Amasa, ẹni tí baba rẹ̀ sì jẹ́ Jeteri ará Iṣmaeli.
17 Abigail deu à luz a Amasa; e o pai de Amasa foi Jéter, o ismaelita.
18 Kalebu ọmọ Hesroni ní ọmọ láti ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀ Asuba (láti ọ̀dọ̀ Jerioti). Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ rẹ̀:
18 Calebe, filho de Hezrom, gerou filhos de Azuba, sua mulher, e de Jeriote; foram estes os filhos desta: Jeser, Sobabe e Ardom.
19 Nígbà tí Asuba sì kú, Kalebu sì fẹ́ Efrata ní aya, ẹni tí ó bí Huri fún un.
19 Morreu Azuba; e Calebe tomou para si a Efrata, da qual lhe nasceu Hur.
20 Huri ni baba Uri, Uri sì jẹ́ baba Besaleli.
20 Hur gerou a Uri, e Uri gerou a Bezalel.
21 Nígbà tí ó yá, Hesroni sì dùbúlẹ̀ pẹ̀lú ọmọbìnrin Makiri baba Gileadi (ó sì ti fẹ́ ní aya láti ìgbà tí ó ti wà ní ẹni ọgọ́ta ọdún) ó sì bí Segubu.
21 Então, Hezrom coabitou com a filha de Maquir, pai de Gileade; tinha ele sessenta anos quando a tomou, e ela deu à luz a Segube.
22 Segubu sì jẹ́ baba Jairi, ẹni tí ó jẹ́ olùdarí ìlú mẹ́tàlélógún ní ilẹ̀ Gileadi.
22 Segube gerou a Jair, que teve vinte e três cidades na terra de Gileade.
23 (Ṣùgbọ́n Geṣuri àti Aramu sì fi agbára gba Hafoti-Jairi, àti Kenati pẹ̀lú gbogbo agbègbè rẹ̀ tí wọn tẹ̀dó sí jẹ́ ọgọ́ta ìlú.)
23 Gesur e Arã tomaram as aldeias de Jair, juntamente com Quenate e suas aldeias, a saber, sessenta lugares; todos estes foram filhos de Maquir, pai de Gileade.
24 Lẹ́yìn tí Hesroni sì kú ni Kalebu Efrata, Abijah ìyàwó rẹ̀ ti Hesroni sì bí Aṣihuri baba Tekoa fún un.
24 Depois da morte de Hezrom, em Calebe-Efrata, Abia, mulher de Hezrom, lhe deu a Azur, pai de Tecoa.
25 Ọmọ Jerahmeeli àkọ́bí Hesroni:
25 Os filhos de Jerameel, primogênito de Hezrom, foram: Rão, o primogênito, Buna, Orém, Ozém e Aías.
26 Jerahmeeli ní ìyàwó mìíràn, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Atara; ó sì jẹ́ ìyá fún Onamu.
26 Teve Jerameel outra mulher, cujo nome era Atara; esta foi a mãe de Onã.
27 Àwọn ọmọ Ramu àkọ́bí Jerahmeeli:
27 Os filhos de Rão, primogênito de Jerameel, foram: Maaz, Jamim e Equer.
28 Àwọn ọmọ Onamu:
28 Foram os filhos de Onã: Samai e Jada; e os filhos de Samai: Nadabe e Abisur.
29 Orúkọ ìyàwó Abiṣuri ni Abihaili ẹni tí ó bí Ahbani àti Molidi.
29 A mulher de Abisur chamava-se Abiail e lhe deu a Abã e a Molide.
30 Àwọn ọmọ Nadabu
30 Os filhos de Nadabe: Selede e Apaim; e Selede morreu sem filhos.
31 Àwọn ọmọ Appaimu:
31 O filho de Apaim: Isi; o filho de Isi: Sesã. E o filho de Sesã: Alai.
32 Àwọn ọmọ Jada, arákùnrin Ṣammai:
32 Os filhos de Jada, irmão de Samai, foram: Jéter e Jônatas; e Jéter morreu sem filhos.
33 Àwọn ọmọ Jonatani:
33 Os filhos de Jônatas: Pelete e Zaza; estes foram os filhos de Jerameel.
34 Ṣeṣani kò sì ní ọmọkùnrin àwọn ọmọbìnrin nìkan ni ó ní.
34 Sesã não teve filhos, mas filhas; e tinha Sesã um servo egípcio, cujo nome era Jara.
35 Ṣeṣani sì fi ọmọ obìnrin rẹ̀ ní aya fún ìránṣẹ́ rẹ̀ Jariha, ó sì bí ọmọ fún tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ Attai.
35 Deu, pois, Sesã sua filha por mulher a Jara, a quem ela deu à luz Atai.
36 Attai sì jẹ́ baba fún Natani,
36 Atai gerou a Natã, e Natã gerou a Zabade.
37 Sabadi ni baba Eflali,
37 Zabade gerou a Eflal, e Eflal, a Obede.
38 Obedi sì ni baba Jehu,
38 Obede gerou a Jeú, e Jeú, a Azarias.
39 Asariah sì ni baba Helesi,
39 Azarias gerou a Heles, e Heles, a Eleasa.
40 Eleasa ni baba Sismai,
40 Eleasa gerou a Sismai, e Sismai, a Salum.
41 Ṣallumu sì ni baba Jekamiah,
41 Salum gerou a Jecamias, e Jecamias, a Elisama.
42 Àwọn ọmọ Kalebu arákùnrin Jerahmeeli:
42 O primogênito de Calebe, irmão de Jerameel, foi Maressa, que foi o pai de Zife; o filho de Maressa foi Abi-Hebrom.
43 Àwọn ọmọ Hebroni:
43 Os filhos de Hebrom: Coré, Tapua, Requém e Sema.
44 Ṣema ni baba Rahamu,
44 Sema gerou a Raão, pai de Jorqueão; e Requém gerou a Samai.
45 Àwọn ọmọ Ṣammai ni Maoni,
45 O filho de Samai foi Maom; e Maom foi o pai de Bete-Zur.
46 Efani obìnrin Kalebu sì ni ìyá
46 Efá, a concubina de Calebe, deu à luz a Harã, a Mosa e a Gazez; e Harã gerou a Gazez.
47 Àwọn ọmọ Jahdai:
47 Os filhos de Jadai: Regém, Jotão, Gesã, Pelete, Efá e Saafe.
48 Maaka obìnrin Kalebu sì ni ìyá
48 De Maaca, concubina, gerou Calebe a Seber e a Tiraná;
49 Ó sì bí Ṣaafu baba Madmana,
49 Maaca deu à luz também a Saafe, pai de Madmana, e a Seva, pai de Macbena e de Gibeá; e Acsa foi filha de Calebe.
50 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Kalebu.
50 Estes foram os filhos de Calebe. Os filhos de Hur, primogênito de Efrata, foram: Sobal, pai de Quiriate-Jearim,
51 Salma baba Bẹtilẹhẹmu àti Harefu baba Beti-Gaderi.
51 Salma, pai dos belemitas, e Harefe, pai de Bete-Gader.
52 Àwọn ọmọ Ṣobali baba Kiriati-Jearimu ni:
52 Os filhos de Sobal, pai de Quiriate-Jearim, foram: Haroé e Hazi-Hamenuote.
53 Àti ìdílé Kiriati-Jearimu: àti àwọn ara Itri, àti àwọn ará Puti, àti àwọn ará Ṣumati àti àwọn ará Miṣraiti: láti ọ̀dọ̀ wọn ni àwọn ọmọ ará Sorati àti àwọn ará Eṣtaoli ti wá.
53 As famílias de Quiriate-Jearim foram: os itritas, os puteus, os sumateus e os misraeus; destes procederam os zoratitas e os estaoleus.
54 Àwọn ọmọ Salma:
54 Os filhos de Salma: Belém e os netofatitas, Atrote-Bete-Joabe e Hazi-Hamanaate, zoreu.
55 àti àwọn ìdílé àwọn akọ̀wé, ẹni tí ń gbé ní Jabesi: àti àwọn ọmọ Tirati àti àwọn ará Ṣimeati àti àwọn ará Sukati. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ará Keni, ẹni tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Hamati, baba ilé Rekabu.
55 As famílias dos escribas que habitavam em Jabez foram os tiratitas, os simeatitas e os sucatitas; são estes os queneus, que vieram de Hamate, pai da casa de Recabe.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.