Salmos 96

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Ẹ kọrin tuntun sí Olúwa,

2 Ẹ kọrin sí Olúwa, yin orúkọ rẹ̀

3 Ẹ sọ ti ògo rẹ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè

4 Nítorí títóbi ní Olúwa ẹni tí ìyìn tọ́ sí;

5 Nítorí asán ni gbogbo àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè

6 Ọlá àti ọláńlá wà ní iwájú rẹ̀

7 Ẹ fi fún Olúwa, ẹ̀yin ìbátan ènìyàn,

8 Ẹ fi ògo tí ó tọ́ sí Olúwa fún un;

9 Ẹ máa sin Olúwa nínú ẹwà ìwà mímọ́ rẹ̀;

10 Sọ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, “Olúwa jẹ ọba.”

11 Jẹ́ kí àwọn ọ̀run kí ó yọ̀, kí ayé sì pariwo

12 Jẹ́ kí oko kún fún ayọ̀, àti ohun gbogbo tí ń bẹ nínú rẹ̀;

13 Wọn yóò kọrin níwájú Olúwa,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 96, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.