Gênesis 10
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NVI
1 Èyí ni ìran àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti, tí àwọn náà sì bí ọmọ lẹ́yìn ìkún omi.
1 Este é o registro da descendência de Sem, Cam e Jafé, filhos de Noé. Os filhos deles nasceram depois do Dilúvio.
2 Àwọn ọmọ Jafeti ni:
2 Estes foram os filhos de Jafé: Gômer, Magogue, Madai, Javã, Tubal, Meseque e Tirás.
3 Àwọn ọmọ Gomeri ni:
3 Estes foram os filhos de Gômer: Asquenaz, Rifate e Togarma.
4 Àwọn ọmọ Jafani ni:
4 Estes foram os filhos de Javã: Elisá, Társis, Quitim e Rodanim.
5 (Láti ọ̀dọ̀ àwọn wọ̀nyí ni àwọn tí ń gbé agbègbè tí omi wà ti tàn ká agbègbè wọn, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, ìdílé wọn ní orílẹ̀-èdè wọn, olúkúlùkù pẹ̀lú èdè tirẹ̀).
5 Deles procedem os povos marítimos, os quais se separaram em seu território, conforme a sua língua, cada um segundo os clãs de suas nações.
6 Àwọn ọmọ Hamu ni:
6 Estes foram os filhos de Cam: Cuxe, Mizraim, Fute e Canaã.
7 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:
7 Estes foram os filhos de Cuxe: Sebá, Havilá, Sabtá, Raamá e Sabtecá. Estes foram os filhos de Raamá: Sabá e Dedã.
8 Kuṣi sì bí Nimrodu, ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
8 Cuxe gerou também Ninrode, o primeiro homem poderoso na terra.
9 Ó sì jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa; nítorí náà ni a ṣe ń wí pé, “Bí Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa.”
9 Ele foi o mais valente dos caçadores, e por isso se diz: "Valente como Ninrode".
10 Ìjọba rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni Babeli, Ereki, Akkadi, Kalne, gbogbo wọn wà ní ilẹ̀ Ṣinari.
10 No início o seu reino abrangia Babel, Ereque, Acade e Calné, na terra de Sinear.
11 Láti ilẹ̀ náà ni ó ti lọ sí Asiria, níbi tí ó ti tẹ ìlú Ninefe, Rehoboti àti Kala,
11 Dessa terra ele partiu para a Assíria, onde fundou Nínive, Reobote-Ir, Calá
12 àti Resini, tí ó wà ní àárín Ninefe àti Kala, tí ó jẹ́ ìlú olókìkí.
12 e Resém, que fica entre Nínive e Calá, a grande cidade.
13 Ejibiti sì bí
13 Mizraim gerou os luditas, os anamitas, os leabitas, os naftuítas,
14 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
14 os patrusitas, os casluítas, dos quais se originaram os filisteus, e os caftoritas.
15 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀,
15 Canaã gerou Sidom, seu filho mais velho, e Hete,
16 Àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
16 como também os jebuseus, os amorreus, os girgaseus,
17 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
17 os heveus, os arqueus, os sineus,
18 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
18 os arvadeus, os zemareus e os hamateus. Posteriormente, os clãs cananeus se espalharam.
19 Ààlà ilẹ̀ àwọn ará Kenaani sì dé Sidoni, lọ sí Gerari títí dé Gasa, lọ sí Sodomu, Gomorra, Adma àti Seboimu, títí dé Laṣa.
19 As fronteiras de Canaã estendiam-se desde Sidom, iam até Gerar, e chegavam a Gaza e, de lá, prosseguiam até Sodoma, Gomorra, Admá e Zeboim, chegando até Lasa.
20 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Hamu, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, àti èdè wọn, ní ìpínlẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
20 São esses os descendentes de Cam, conforme seus clãs e línguas, em seus territórios e nações.
21 A bí àwọn ọmọ fún Ṣemu tí Jafeti jẹ́ ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin: Ṣemu sì ni baba gbogbo àwọn ọmọ Eberi.
21 Sem, irmão mais velho de Jafé, também gerou filhos. Sem foi o antepassado de todos os filhos de Héber.
22 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:
22 Estes foram os filhos de Sem: Elão, Assur, Arfaxade, Lude e Arã.
23 Àwọn ọmọ Aramu ni:
23 Estes foram os filhos de Arã: Uz, Hul, Géter e Meseque.
24 Arfakṣadi sì bí Ṣela,
24 Arfaxade gerou Salá, e este gerou Héber.
25 Eberi sì bí ọmọ méjì:
25 A Héber nasceram dois filhos: Um deles se chamou Pelegue, porque em sua época a terra foi dividida; seu irmão chamou-se Joctã.
26 Joktani sì bí
26 Joctã gerou Almodá, Salefe, Hazarmavé, Jerá,
27 Hadoramu, Usali, Dikla,
27 Hadorão, Uzal, Dicla,
28 Obali, Abimaeli, Ṣeba.
28 Obal, Abimael, Sabá,
29 Ofiri, Hafila àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
29 Ofir, Havilá e Jobabe. Todos esses foram filhos de Joctã.
30 Agbègbè ibi tí wọn ń gbé bẹ̀rẹ̀ láti Meṣa títí dé Sefari, ní àwọn ilẹ̀ tó kún fún òkè ní ìlà-oòrùn.
30 A região onde viviam estendia-se de Messa até Sefar, nas colinas ao leste.
31 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Ṣemu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, ní èdè wọn, ní ilẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
31 São esses os descendentes de Sem, conforme seus clãs e línguas, em seus territórios e nações.
32 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Noa gẹ́gẹ́ bí ìran wọn, ní orílẹ̀-èdè wọn. Ní ipasẹ̀ wọn ni àwọn ènìyàn ti tàn ká ilẹ̀ ayé lẹ́yìn ìkún omi.
32 São esses os clãs dos filhos de Noé, distribuídos em suas nações, conforme a história da sua descendência. A partir deles, os povos se dispersaram pela terra, depois do Dilúvio.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Gênesis 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.