Gênesis 10
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH
1 Èyí ni ìran àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti, tí àwọn náà sì bí ọmọ lẹ́yìn ìkún omi.
1 São estes os descendentes de Sem, Cam e Jafé, os filhos de Noé. Aos três nasceram filhos depois do dilúvio.
2 Àwọn ọmọ Jafeti ni:
2 Os filhos de Jafé foram Gomer, Magogue, Madai, Javã, Tubal, Meseque e Tirás.
3 Àwọn ọmọ Gomeri ni:
3 Os filhos de Gomer foram Asquenaz, Rifate e Togarma.
4 Àwọn ọmọ Jafani ni:
4 Os descendentes de Javã foram os povos de Elisá, Espanha, Chipre e Rodes.
5 (Láti ọ̀dọ̀ àwọn wọ̀nyí ni àwọn tí ń gbé agbègbè tí omi wà ti tàn ká agbègbè wọn, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, ìdílé wọn ní orílẹ̀-èdè wọn, olúkúlùkù pẹ̀lú èdè tirẹ̀).
5 Esses foram os descendentes de Jafé; eles moram no litoral e nas ilhas, cada povo e cada família na sua própria terra, com a sua própria língua.
6 Àwọn ọmọ Hamu ni:
6 Os filhos de Cam foram Cuche, Egito, Líbia e Canaã.
7 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:
7 Os filhos de Cuche foram Sebá, Havilá, Sabtá, Raamá e Sabteca. Os filhos de Raamá foram Sabá e Dedã.
8 Kuṣi sì bí Nimrodu, ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
8 Cuche foi pai de Ninrode, o primeiro grande conquistador do mundo.
9 Ó sì jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa; nítorí náà ni a ṣe ń wí pé, “Bí Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa.”
9 Com a ajuda de Deus, o Senhor , ele se tornou um caçador famoso, e é por isso que se diz: “Seja igual a Ninrode, que com a ajuda do Senhor foi um grande caçador.”
10 Ìjọba rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni Babeli, Ereki, Akkadi, Kalne, gbogbo wọn wà ní ilẹ̀ Ṣinari.
10 No começo faziam parte do seu reino as cidades de Babilônia, Ereque e Acade, todas as três em Sinar.
11 Láti ilẹ̀ náà ni ó ti lọ sí Asiria, níbi tí ó ti tẹ ìlú Ninefe, Rehoboti àti Kala,
11 Daquela região Ninrode foi para a Assíria e ali construiu as cidades de Nínive, Reobote-Ir, Calá
12 àti Resini, tí ó wà ní àárín Ninefe àti Kala, tí ó jẹ́ ìlú olókìkí.
12 e Resém, que fica entre Nínive e a grande cidade de Calá.
13 Ejibiti sì bí
13 Os descendentes de Egito foram os povos da Lídia, Anam, Leabe, Naftu,
14 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
14 Patrus, Caslu e de Creta, de quem os filisteus descendem.
15 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀,
15 Canaã foi pai de dois filhos: Sidom, o mais velho, e Hete.
16 Àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
16 De Canaã também descendem os jebuseus, os amorreus, os girgaseus,
17 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
17 os heveus, os arquitas, os sineus,
18 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
18 os arvaditas, os zemareus e os hamateus.
19 Ààlà ilẹ̀ àwọn ará Kenaani sì dé Sidoni, lọ sí Gerari títí dé Gasa, lọ sí Sodomu, Gomorra, Adma àti Seboimu, títí dé Laṣa.
19 O território dos cananeus se estendeu para o sul desde Sidom até Gerar, perto de Gaza; e para o leste foi até Sodoma, Gomorra, Admá e Zeboim, perto de Lasa.
20 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Hamu, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, àti èdè wọn, ní ìpínlẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
20 Esses foram os descendentes de Cam, cada povo e cada família na sua própria terra, com a sua própria língua.
21 A bí àwọn ọmọ fún Ṣemu tí Jafeti jẹ́ ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin: Ṣemu sì ni baba gbogbo àwọn ọmọ Eberi.
21 Sem, o irmão mais velho de Jafé, foi o pai de todos os hebreus.
22 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:
22 Os filhos de Sem foram Elão, Assur, Arpaxade, Lude e Arã.
23 Àwọn ọmọ Aramu ni:
23 Os filhos de Arã foram Uz, Hul, Géter e Más.
24 Arfakṣadi sì bí Ṣela,
24 Arpaxade foi o pai de Selá, e Selá foi o pai de Éber.
25 Eberi sì bí ọmọ méjì:
25 Éber foi pai de dois filhos: um se chamava Pelegue porque no seu tempo os povos do mundo foram divididos; o seu irmão se chamava Joctã.
26 Joktani sì bí
26 Joctã foi pai de Almodá, Selefe, Hazar-Mavé, Jera,
27 Hadoramu, Usali, Dikla,
27 Adonirão, Uzal, Dicla,
28 Obali, Abimaeli, Ṣeba.
28 Obal, Abimael, Sabá,
29 Ofiri, Hafila àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
29 Ofir, Havilá e Jobabe. Todos estes foram filhos de Joctã.
30 Agbègbè ibi tí wọn ń gbé bẹ̀rẹ̀ láti Meṣa títí dé Sefari, ní àwọn ilẹ̀ tó kún fún òkè ní ìlà-oòrùn.
30 Eles viveram nas terras que vão desde a região de Mesa até Sefar, na região montanhosa do Leste.
31 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Ṣemu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, ní èdè wọn, ní ilẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
31 Estes foram os descendentes de Sem, cada povo e cada família na sua própria terra, com a sua própria língua.
32 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Noa gẹ́gẹ́ bí ìran wọn, ní orílẹ̀-èdè wọn. Ní ipasẹ̀ wọn ni àwọn ènìyàn ti tàn ká ilẹ̀ ayé lẹ́yìn ìkún omi.
32 São essas as famílias dos filhos de Noé, nação por nação, de acordo com as várias linhas de descendentes. Depois do dilúvio todas as nações da terra descenderam de Noé.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Gênesis 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.