Gênesis 10

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ACF

Sair da comparação
ACF Almeida Corrigida Fiel
1 Èyí ni ìran àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti, tí àwọn náà sì bí ọmọ lẹ́yìn ìkún omi.
1 Estas, pois, são as gerações dos filhos de Noé: Sem, Cão e Jafé; e nasceram-lhes filhos depois do dilúvio.
2 Àwọn ọmọ Jafeti ni:
2 Os filhos de Jafé são: Gomer, Magogue, Madai, Javã, Tubal, Meseque e Tiras.
3 Àwọn ọmọ Gomeri ni:
3 E os filhos de Gomer são: Asquenaz, Rifate e Togarma.
4 Àwọn ọmọ Jafani ni:
4 E os filhos de Javã são: Elisá, Társis, Quitim e Dodanim.
5 (Láti ọ̀dọ̀ àwọn wọ̀nyí ni àwọn tí ń gbé agbègbè tí omi wà ti tàn ká agbègbè wọn, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, ìdílé wọn ní orílẹ̀-èdè wọn, olúkúlùkù pẹ̀lú èdè tirẹ̀).
5 Por estes foram repartidas as ilhas dos gentios nas suas terras, cada qual segundo a sua língua, segundo as suas famílias, entre as suas nações.
6 Àwọn ọmọ Hamu ni:
6 E os filhos de Cão são: Cuxe, Mizraim, Pute e Canaã.
7 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:
7 E os filhos de Cuxe são: Sebá, Havilá, Sabtá, Raamá e Sabtecá; e os filhos de Raamá: Sebá e Dedã.
8 Kuṣi sì bí Nimrodu, ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
8 E Cuxe gerou a Ninrode; este começou a ser poderoso na terra. 9
9 Ó sì jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa; nítorí náà ni a ṣe ń wí pé, “Bí Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa.”
9 E este foi poderoso caçador diante da face do Senhor; por isso se diz: Como Ninrode, poderoso caçador diante do Senhor.
10 Ìjọba rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni Babeli, Ereki, Akkadi, Kalne, gbogbo wọn wà ní ilẹ̀ Ṣinari.
10 E o princípio do seu reino foi Babel, Ereque, Acade e Calné, na terra de Sinar.
11 Láti ilẹ̀ náà ni ó ti lọ sí Asiria, níbi tí ó ti tẹ ìlú Ninefe, Rehoboti àti Kala,
11 Desta mesma terra saiu à Assíria e edificou a Nínive, Reobote-Ir, Calá,
12 àti Resini, tí ó wà ní àárín Ninefe àti Kala, tí ó jẹ́ ìlú olókìkí.
12 E Resen, entre Nínive e Calá (esta é a grande cidade).
13 Ejibiti sì bí
13 E Mizraim gerou a Ludim, a Anamim, a Leabim, a Naftuim,
14 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
14 A Patrusim e a Casluim (donde saíram os filisteus) e a Caftorim.
15 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀,
15 E Canaã gerou a Sidom, seu primogênito, e a Hete;
16 Àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
16 E ao jebuseu, ao amorreu, ao girgaseu,
17 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
17 E ao heveu, ao arqueu, ao sineu,
18 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
18 E ao arvadeu, ao zemareu, e ao hamateu, e depois se espalharam as famílias dos cananeus.
19 Ààlà ilẹ̀ àwọn ará Kenaani sì dé Sidoni, lọ sí Gerari títí dé Gasa, lọ sí Sodomu, Gomorra, Adma àti Seboimu, títí dé Laṣa.
19 E foi o termo dos cananeus desde Sidom, indo para Gerar, até Gaza; indo para Sodoma e Gomorra, Admá e Zeboim, até Lasa.
20 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Hamu, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, àti èdè wọn, ní ìpínlẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
20 Estes são os filhos de Cão segundo as suas famílias, segundo as suas línguas, em suas terras, em suas nações.
21 A bí àwọn ọmọ fún Ṣemu tí Jafeti jẹ́ ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin: Ṣemu sì ni baba gbogbo àwọn ọmọ Eberi.
21 E a Sem nasceram filhos, e ele é o pai de todos os filhos de Éber, o irmão mais velho de Jafé.
22 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:
22 Os filhos de Sem são: Elão, Assur, Arfaxade, Lude e Arã.
23 Àwọn ọmọ Aramu ni:
23 E os filhos de Arã são: Uz, Hul, Geter e Más.
24 Arfakṣadi sì bí Ṣela,
24 E Arfaxade gerou a Selá; e Selá gerou a Éber.
25 Eberi sì bí ọmọ méjì:
25 E a Éber nasceram dois filhos: o nome de um foi Pelegue, porquanto em seus dias se repartiu a terra, e o nome do seu irmão foi Joctã.
26 Joktani sì bí
26 E Joctã gerou a Almodá, a Selefe, a Hazarmavé, a Jerá,
27 Hadoramu, Usali, Dikla,
27 A Hadorão, a Usal, a Dicla,
28 Obali, Abimaeli, Ṣeba.
28 A Obal, a Abimael, a Sebá,
29 Ofiri, Hafila àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
29 A Ofir, a Havilá e a Jobabe; todos estes foram filhos de Joctã.
30 Agbègbè ibi tí wọn ń gbé bẹ̀rẹ̀ láti Meṣa títí dé Sefari, ní àwọn ilẹ̀ tó kún fún òkè ní ìlà-oòrùn.
30 E foi a sua habitação desde Messa, indo para Sefar, montanha do oriente.
31 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Ṣemu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, ní èdè wọn, ní ilẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
31 Estes são os filhos de Sem segundo as suas famílias, segundo as suas línguas, nas suas terras, segundo as suas nações.
32 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Noa gẹ́gẹ́ bí ìran wọn, ní orílẹ̀-èdè wọn. Ní ipasẹ̀ wọn ni àwọn ènìyàn ti tàn ká ilẹ̀ ayé lẹ́yìn ìkún omi.
32 Estas são as famílias dos filhos de Noé segundo as suas gerações, nas suas nações; e destes foram divididas as nações na terra depois do dilúvio.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Gênesis 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.