Gênesis 10

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NAA

Sair da comparação
NAA Nova Almeida Atualizada 2017
1 Èyí ni ìran àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti, tí àwọn náà sì bí ọmọ lẹ́yìn ìkún omi.
1 São estas as gerações de Sem, Cam e Jafé, os filhos de Noé. A eles nasceram filhos depois do dilúvio.
2 Àwọn ọmọ Jafeti ni:
2 Os filhos de Jafé foram: Gomer, Magogue, Madai, Javã, Tubal, Meseque e Tiras.
3 Àwọn ọmọ Gomeri ni:
3 Os filhos de Gomer foram: Asquenaz, Rifate e Togarma.
4 Àwọn ọmọ Jafani ni:
4 Os filhos de Javã foram: Elisá, Társis, Quitim e Dodanim.
5 (Láti ọ̀dọ̀ àwọn wọ̀nyí ni àwọn tí ń gbé agbègbè tí omi wà ti tàn ká agbègbè wọn, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, ìdílé wọn ní orílẹ̀-èdè wọn, olúkúlùkù pẹ̀lú èdè tirẹ̀).
5 Estes repartiram entre si as ilhas das nações nas suas terras, cada qual segundo a sua língua, segundo as suas famílias, em suas nações.
6 Àwọn ọmọ Hamu ni:
6 Os filhos de Cam foram: Cuxe, Mizraim, Pute e Canaã.
7 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:
7 Os filhos de Cuxe foram: Sebá, Havilá, Sabtá, Raamá e Sabtecá; e os filhos de Raamá: Sabá e Dedã.
8 Kuṣi sì bí Nimrodu, ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
8 Cuxe gerou Ninrode, que começou a ser poderoso na terra.
9 Ó sì jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa; nítorí náà ni a ṣe ń wí pé, “Bí Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa.”
9 Foi valente caçador diante do Senhor . Daí dizer-se: “Como Ninrode, poderoso caçador diante do Senhor .”
10 Ìjọba rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni Babeli, Ereki, Akkadi, Kalne, gbogbo wọn wà ní ilẹ̀ Ṣinari.
10 O princípio do seu reino foi Babel, Ereque, Acade e Calné, na terra de Sinar.
11 Láti ilẹ̀ náà ni ó ti lọ sí Asiria, níbi tí ó ti tẹ ìlú Ninefe, Rehoboti àti Kala,
11 Daquela terra ele foi para a Assíria e edificou Nínive, Reobote-Ir e Calá.
12 àti Resini, tí ó wà ní àárín Ninefe àti Kala, tí ó jẹ́ ìlú olókìkí.
12 E, entre Nínive e Calá, a grande cidade de Resém.
13 Ejibiti sì bí
13 Mizraim gerou Ludim, Anamim, Leabim, Naftuim,
14 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
14 Patrusim, Casluim (de quem descendem os filisteus) e Caftorim.
15 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀,
15 Canaã gerou Sidom, seu primogênito, e Hete,
16 Àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
16 e também os jebuseus, os amorreus, os girgaseus,
17 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
17 os heveus, os arqueus, os sineus,
18 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
18 os arvadeus, os zemareus e os hamateus. Depois as famílias dos cananeus se espalharam.
19 Ààlà ilẹ̀ àwọn ará Kenaani sì dé Sidoni, lọ sí Gerari títí dé Gasa, lọ sí Sodomu, Gomorra, Adma àti Seboimu, títí dé Laṣa.
19 E a fronteira dos cananeus foi desde Sidom, indo para Gerar, até Gaza, indo para Sodoma, Gomorra, Admá e Zeboim, até Lasa.
20 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Hamu, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, àti èdè wọn, ní ìpínlẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
20 São estes os filhos de Cam, segundo as suas famílias, segundo as suas línguas, em suas terras, em suas nações.
21 A bí àwọn ọmọ fún Ṣemu tí Jafeti jẹ́ ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin: Ṣemu sì ni baba gbogbo àwọn ọmọ Eberi.
21 A Sem, que foi pai de todos os filhos de Héber e irmão mais velho de Jafé, também nasceram filhos.
22 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:
22 Os filhos de Sem foram: Elão, Assur, Arfaxade, Lude e Arã.
23 Àwọn ọmọ Aramu ni:
23 Os filhos de Arã foram: Uz, Hul, Geter e Más.
24 Arfakṣadi sì bí Ṣela,
24 Arfaxade gerou Salá, e Salá gerou Héber.
25 Eberi sì bí ọmọ méjì:
25 A Héber nasceram dois filhos: o nome de um foi Pelegue, porque em seus dias se repartiu a terra; e o nome de seu irmão foi Joctã.
26 Joktani sì bí
26 Joctã gerou Almodá, Selefe, Hazar-Mavé, Jerá,
27 Hadoramu, Usali, Dikla,
27 Hadorão, Uzal, Dicla,
28 Obali, Abimaeli, Ṣeba.
28 Obal, Abimael, Sabá,
29 Ofiri, Hafila àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
29 Ofir, Havilá e Jobabe. Todos estes foram filhos de Joctã.
30 Agbègbè ibi tí wọn ń gbé bẹ̀rẹ̀ láti Meṣa títí dé Sefari, ní àwọn ilẹ̀ tó kún fún òkè ní ìlà-oòrùn.
30 E habitaram desde Messa, indo para Sefar, montanha do Oriente.
31 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Ṣemu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, ní èdè wọn, ní ilẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
31 São estes os filhos de Sem, segundo as suas famílias, segundo as suas línguas, em suas terras, em suas nações.
32 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Noa gẹ́gẹ́ bí ìran wọn, ní orílẹ̀-èdè wọn. Ní ipasẹ̀ wọn ni àwọn ènìyàn ti tàn ká ilẹ̀ ayé lẹ́yìn ìkún omi.
32 São estas as famílias dos filhos de Noé, segundo as suas gerações, nas suas nações; e destes foram disseminadas as nações na terra, depois do dilúvio.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Gênesis 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.