Gênesis 10

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Èyí ni ìran àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti, tí àwọn náà sì bí ọmọ lẹ́yìn ìkún omi.
1 Ora, estas são as gerações dos filhos de Noé, Sem, Cam e Jafé. E a eles nasceram filhos depois do dilúvio.
2 Àwọn ọmọ Jafeti ni:
2 Os filhos de Jafé: Gomer, e Magogue, e Madai, e Javã, e Tubal, e Meseque, e Tiras.
3 Àwọn ọmọ Gomeri ni:
3 E os filhos de Gomer: Asquenaz, e Rifate, e Togarma.
4 Àwọn ọmọ Jafani ni:
4 E os filhos de Javã: Elisá, e Társis, Quitim, e Dodanim.
5 (Láti ọ̀dọ̀ àwọn wọ̀nyí ni àwọn tí ń gbé agbègbè tí omi wà ti tàn ká agbègbè wọn, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, ìdílé wọn ní orílẹ̀-èdè wọn, olúkúlùkù pẹ̀lú èdè tirẹ̀).
5 Por estes, foram divididas as ilhas dos Gentios nas suas terras, cada qual segundo a sua língua, segundo as suas famílias, entre as suas nações.
6 Àwọn ọmọ Hamu ni:
6 E os filhos de Cam: Cuxe, e Mizraim, e Pute, e Canaã.
7 Àwọn ọmọ Kuṣi ni:
7 E os filhos de Cuxe: Sebá, e Havilá, e Sabtá, e Raamá, e Sabtecá; e os filhos de Raamá: Sebá e Dedã.
8 Kuṣi sì bí Nimrodu, ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
8 E Cuxe gerou Ninrode; este começou a ser poderoso na terra.
9 Ó sì jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa; nítorí náà ni a ṣe ń wí pé, “Bí Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa.”
9 Ele foi um caçador poderoso diante do SENHOR, pelo que é dito: Como Ninrode, poderoso caçador diante do SENHOR.
10 Ìjọba rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni Babeli, Ereki, Akkadi, Kalne, gbogbo wọn wà ní ilẹ̀ Ṣinari.
10 E no começo do seu reino estavam Babel, e Ereque, e Acade, e Calné na terra de Sinar.
11 Láti ilẹ̀ náà ni ó ti lọ sí Asiria, níbi tí ó ti tẹ ìlú Ninefe, Rehoboti àti Kala,
11 Daquela terra saiu Assur e edificou Nínive, e a cidade de Reobote-Ir, e Calá.
12 àti Resini, tí ó wà ní àárín Ninefe àti Kala, tí ó jẹ́ ìlú olókìkí.
12 E Resen, entre Nínive e Calá; esta mesma é uma grande cidade.
13 Ejibiti sì bí
13 E Mizraim gerou Ludim, e Anamim, e Leabim, e Naftuim,
14 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
14 e Patrusim, e Casluim (de quem vieram os filisteus), e Caftorim.
15 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀,
15 E Canaã gerou Sidom, seu primogênito, e Hete,
16 Àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
16 e o jebuseu, e o amorreu, e o girgaseu,
17 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
17 e o heveu, e o arqueu, e o sineu,
18 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati.
18 e o arvadeu, e o zemareu, e o hamateu, e depois as famílias dos cananeus foram espalhadas.
19 Ààlà ilẹ̀ àwọn ará Kenaani sì dé Sidoni, lọ sí Gerari títí dé Gasa, lọ sí Sodomu, Gomorra, Adma àti Seboimu, títí dé Laṣa.
19 E o termo dos cananeus era desde Sidom, quando se vai para Gerar, até Gaza; quando se vai para Sodoma, e Gomorra, e Admá, e Zeboim até Lasa.
20 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Hamu, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, àti èdè wọn, ní ìpínlẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
20 Estes são os filhos de Cam, segundo as suas famílias, segundo as suas línguas, em suas terras, e em suas nações.
21 A bí àwọn ọmọ fún Ṣemu tí Jafeti jẹ́ ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin: Ṣemu sì ni baba gbogbo àwọn ọmọ Eberi.
21 A Sem também nasceram filhos, o pai de todos os filhos de Éber, e o irmão mais velho de Jafé.
22 Àwọn ọmọ Ṣemu ni:
22 Os filhos de Sem: Elão, e Assur, e Arfaxade, e Lude, e Arã.
23 Àwọn ọmọ Aramu ni:
23 E os filhos de Arã: Uz, e Hul, e Geter, e Más.
24 Arfakṣadi sì bí Ṣela,
24 E Arfaxade gerou Salá; e Salá gerou Éber.
25 Eberi sì bí ọmọ méjì:
25 E a Éber nasceram dois filhos: o nome de um foi Pelegue, pois em seus dias foi dividida a terra; e o nome do seu irmão foi Joctã.
26 Joktani sì bí
26 E Joctã gerou Almodá, e Selefe, e Hazarmavé, e Jerá,
27 Hadoramu, Usali, Dikla,
27 e Hadorão, e Usal, e Dicla,
28 Obali, Abimaeli, Ṣeba.
28 e Obal, e Abimael, e Sabá,
29 Ofiri, Hafila àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
29 e Ofir, e Havilá, e Jobabe; todos estes eram filhos de Joctã.
30 Agbègbè ibi tí wọn ń gbé bẹ̀rẹ̀ láti Meṣa títí dé Sefari, ní àwọn ilẹ̀ tó kún fún òkè ní ìlà-oòrùn.
30 E sua habitação foi desde Messa, quando se vai para Sefar, um monte do leste.
31 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Ṣemu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, ní èdè wọn, ní ilẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
31 Estes são os filhos de Sem, segundo as suas famílias, segundo as suas línguas, em suas terras, em suas nações.
32 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Noa gẹ́gẹ́ bí ìran wọn, ní orílẹ̀-èdè wọn. Ní ipasẹ̀ wọn ni àwọn ènìyàn ti tàn ká ilẹ̀ ayé lẹ́yìn ìkún omi.
32 Estas são as famílias dos filhos de Noé, segundo as suas gerações, em suas nações; e por estas foram as nações divididas na terra depois do dilúvio.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Gênesis 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.