Jó 27

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Pẹ̀lúpẹ̀lú Jobu sì tún sọkún ọ̀rọ̀ òwe rẹ̀, ó sì wí pé,

2 “Bí Ọlọ́run ti ń bẹ, ẹni tí ó gba ìdájọ́ mi lọ,

3 níwọ́n ìgbà tí ẹ̀mí mi ń bẹ nínú mi,

4 Ètè mi kì yóò sọ̀rọ̀ èké,

5 Kí a má rí i pé èmi ń dá yín láre;

6 Òdodo mi ni èmi dìímú ṣinṣin, èmi kì yóò sì jọ̀wọ́ rẹ̀ lọ́wọ́;

7 “Kí ọ̀tá mi kí ó dàbí ènìyàn búburú,

8 Nítorí kí ni ìrètí àgàbàgebè,

9 Ọlọ́run yóò ha gbọ́ àdúrà rẹ̀,

10 Òun ha le ní inú dídùn sí Olódùmarè?

11 “Èmi ó kọ́ yín ní ẹ̀kọ́ ní ti ọwọ́ Ọlọ́run:

12 Kíyèsi i, gbogbo yín ni ó ti rí i;

13 “Ẹ̀yin ni ìpín ènìyàn búburú lọ́dọ̀ Ọlọ́run,

14 Bí àwọn ọmọ rẹ bá di púpọ̀, fún idà ni;

15 Àwọn tí ó kù nínú tirẹ̀ ni a ó sìnkú nínú àjàkálẹ̀-ààrùn:

16 Bí ó tilẹ̀ kó fàdákà jọ bí erùpẹ̀,

17 àwọn ohun tí ó tò jọ àwọn olóòtítọ́ ni yóò lò ó;

18 Òun kọ́ ilé rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí kòkòrò aṣọ,

19 Ọlọ́rọ̀ yóò dùbúlẹ̀, ṣùgbọ́n òun kì yóò túnṣe bẹ́ẹ̀ mọ́,

20 Ẹ̀rù ńlá bà á bí omi ṣíṣàn;

21 Ẹ̀fúùfù ìlà-oòrùn gbé e lọ, òun sì lọ;

22 Nítorí pé Olódùmarè yóò kọlù ú, kì yóò sì dá sí;

23 Àwọn ènìyàn yóò sì ṣápẹ́ sí i lórí,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Jó 27, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.