1 Pẹ̀lúpẹ̀lú Jobu sì tún sọkún ọ̀rọ̀ òwe rẹ̀, ó sì wí pé,
2 “Bí Ọlọ́run ti ń bẹ, ẹni tí ó gba ìdájọ́ mi lọ,
3 níwọ́n ìgbà tí ẹ̀mí mi ń bẹ nínú mi,
4 Ètè mi kì yóò sọ̀rọ̀ èké,
5 Kí a má rí i pé èmi ń dá yín láre;
6 Òdodo mi ni èmi dìímú ṣinṣin, èmi kì yóò sì jọ̀wọ́ rẹ̀ lọ́wọ́;
7 “Kí ọ̀tá mi kí ó dàbí ènìyàn búburú,
8 Nítorí kí ni ìrètí àgàbàgebè,
9 Ọlọ́run yóò ha gbọ́ àdúrà rẹ̀,
10 Òun ha le ní inú dídùn sí Olódùmarè?
11 “Èmi ó kọ́ yín ní ẹ̀kọ́ ní ti ọwọ́ Ọlọ́run:
12 Kíyèsi i, gbogbo yín ni ó ti rí i;
13 “Ẹ̀yin ni ìpín ènìyàn búburú lọ́dọ̀ Ọlọ́run,
14 Bí àwọn ọmọ rẹ bá di púpọ̀, fún idà ni;
15 Àwọn tí ó kù nínú tirẹ̀ ni a ó sìnkú nínú àjàkálẹ̀-ààrùn:
16 Bí ó tilẹ̀ kó fàdákà jọ bí erùpẹ̀,
17 àwọn ohun tí ó tò jọ àwọn olóòtítọ́ ni yóò lò ó;
18 Òun kọ́ ilé rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí kòkòrò aṣọ,
19 Ọlọ́rọ̀ yóò dùbúlẹ̀, ṣùgbọ́n òun kì yóò túnṣe bẹ́ẹ̀ mọ́,
20 Ẹ̀rù ńlá bà á bí omi ṣíṣàn;
21 Ẹ̀fúùfù ìlà-oòrùn gbé e lọ, òun sì lọ;
22 Nítorí pé Olódùmarè yóò kọlù ú, kì yóò sì dá sí;
23 Àwọn ènìyàn yóò sì ṣápẹ́ sí i lórí,