Cânticos 1

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Orin, àwọn orin tí í ṣe orin Solomoni.

2 Fi ìfẹnukonu ìfẹ́ kò mí ní ẹnu,

3 Òórùn ìkunra rẹ fanimọ́ra.

4 Fà mí lọ pẹ̀lú rẹ, kí a lọ kíákíá

5 Èmi dúdú mo sì ní ẹwà.

6 Má ṣe wò mí nítorí wí pé mo dúdú,

7 Wí fún mi, ìwọ ẹni tí ọkàn mí fẹ́,

8 Bí ìwọ kò bá mọ̀,

9 Olùfẹ́ mi,

10 Ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ dára ní ohun ọ̀ṣọ́,

11 A ó fi wúrà ṣe òrùka etí fún ọ,

12 Nígbà tí ọba wà ní orí ìjókòó rẹ̀,

13 Ìdì òjìá ni olùfẹ́ mi jẹ sí mi,

14 Bí ìdì ìtànná Henina ni olùfẹ́ mi rí sí mi

15 Báwo ni o ti lẹ́wà tó, olólùfẹ́ mi!

16 Báwo ni o ṣe dára tó, olùfẹ́ mi!

17 Ìtànṣán ilé wa jẹ́ ti igi kedari

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Cânticos 1, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.