Provérbios 2
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NVT
1 Ọmọ mi, bí ìwọ bá gba ọ̀rọ̀ mi,
1 Meu filho, preste atenção às minhas palavras e guarde meus mandamentos como um tesouro.
2 tí ìwọ dẹtí rẹ sílẹ̀ sí ọgbọ́n
2 Dê ouvidos à sabedoria e concentre o coração no entendimento.
3 àní, bí ìwọ bá ké tọ ìmọ̀ lẹ́yìn,
3 Clame por inteligência e peça entendimento.
4 bí ìwọ bá ṣàfẹ́rí rẹ̀ bí i fàdákà
4 Busque-os como a prata, procure-os como a tesouros escondidos.
5 Nígbà náà ni ìwọ yóò bẹ̀rù Olúwa,
5 Então entenderá o que é o temor do S enhor e obterá o conhecimento de Deus.
6 Nítorí Olúwa ni ó ń fún ni ní ọgbọ́n,
6 Pois o S enhor concede sabedoria; de sua boca vêm conhecimento e entendimento.
7 Ó to ìgbàlà fún àwọn olódodo,
7 Ele reserva bom senso aos honestos e é escudo para os íntegros.
8 Ó pa ipa ọ̀nà ìdájọ́ mọ́
8 Guarda os caminhos dos justos e protege seus fiéis por onde andam.
9 Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ òdodo àti ìdájọ́,
9 Então você entenderá o que é certo, justo e imparcial e saberá o bom caminho a seguir.
10 Nítorí ọgbọ́n yóò wọ inú ọkàn rẹ
10 Pois a sabedoria entrará em seu coração, e o conhecimento o encherá de alegria.
11 Ìmòye yóò pa ọ mọ́
11 As escolhas sábias o guardarão, e o entendimento o protegerá.
12 Ọgbọ́n yóò gbà ọ́ là kúrò ní ọ̀nà àwọn ènìyàn búburú,
12 A sabedoria o livrará das ações dos maus, daqueles cujas palavras são perversas.
13 ẹni tí ó kúrò ní ọ̀nà ìdúró ṣinṣin
13 Eles se afastam do rumo certo e andam por caminhos sombrios.
14 ẹni tí ó yọ̀ nínú ṣíṣe búburú,
14 Têm prazer em praticar o mal e aplaudem a maldade dos perversos.
15 ọ̀nà ẹni tí ó wọ́
15 Suas ações são desonestas, e seus caminhos, tortuosos.
16 Yóò gba ìwọ pẹ̀lú là kúrò lọ́wọ́ àwọn àjèjì obìnrin,
16 A sabedoria o livrará da mulher imoral, das palavras sedutoras da promíscua.
17 ẹni tí ó ti kọ ọkọ àkọ́fẹ́ ìgbà èwe rẹ̀ sílẹ̀
17 Ela abandona o marido, o companheiro de sua juventude, e ignora a aliança que fez diante de Deus.
18 Nítorí ilé rẹ̀ jẹ́ ọ̀nà sí ikú
18 Entrar na casa dela leva à morte; é a estrada para a sepultura.
19 Kò sẹ́ni tó lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ tí ó padà
19 O homem que a visita está perdido; jamais alcançará os caminhos da vida.
20 Bẹ́ẹ̀ ni ìwọ yóò rìn ní ọ̀nà àwọn ènìyàn rere
20 Portanto, siga os passos dos bons e permaneça nos caminhos dos justos.
21 Nítorí ẹni dídúró ṣinṣin yóò gbé ní ilé náà
21 Pois os retos viverão na terra, e os íntegros nela permanecerão.
22 Ṣùgbọ́n a ó ké ènìyàn búburú kúrò lórí ilẹ̀ náà
22 Os perversos, porém, serão eliminados da terra, e os desleais, arrancados dela.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Provérbios 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.