Neemias 7
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Lẹ́yìn ìgbà tí a tún odi mọ tán tí mo sì ri àwọn ìlẹ̀kùn sí ààyè wọn, a sì yan àwọn aṣọ́bodè, àwọn akọrin àti àwọn Lefi.
1 Ora, aconteceu que, quando a muralha estava edificada, e eu tinha posto as portas, e os porteiros e os cantores e os levitas foram nomeados,
2 Mo fún Hanani arákùnrin mi pẹ̀lú Hananiah olórí ilé ìṣọ́ ní àṣẹ lórí Jerusalẹmu, nítorí tí ó jẹ́ ènìyàn olóòtítọ́, ó sì bẹ̀rù Ọlọ́run jù bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ti ṣe lọ.
2 que eu dei ao meu irmão Hanani, e Hananias, o governante do palácio, incumbência sobre Jerusalém; porque ele era um homem fiel, e temia a Deus mais do que muitos.
3 Mo sọ fún wọn pé, “A kò gbọdọ̀ ṣí ìlẹ̀kùn Jerusalẹmu títí oòrùn yóò fi mú. Nígbà tí àwọn aṣọ́bodè bá sì wà lẹ́nu iṣẹ́, jẹ́ kí wọn ti ìlẹ̀kùn kí wọn sì há wọn. Bákan náà, yàn nínú àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́. Àwọn mìíràn níbi tí a pín wọn sí àti àwọn mìíràn ní tòsí ilé e wọn.”
3 E eu lhes disse: Não deixeis que os portões de Jerusalém sejam abertos até que o sol esteja quente; e, enquanto eles estiverem ali de pé, que fechem as portas, e travem-nas com barras; e indiquem guardas dos habitantes de Jerusalém, cada um na sua guarda, e cada um para estar na frente da sua casa.
4 Ìlú náà tóbi ó sì ní ààyè, ṣùgbọ́n ènìyàn inú rẹ̀ kéré, a kò sì tí ì tún àwọn ilé inú rẹ̀ kọ́.
4 Ora, a cidade era extensa e grande; mas o povo nela era pouco, e as casas não estavam edificadas.
5 Nígbà náà ni Ọlọ́run mi fi sí mi ní ọkàn láti kó àwọn ọlọ́lá, àwọn ìjòyè, àti àwọn ènìyàn jọ fún ìforúkọsílẹ̀ ní ìdílé ìdílé. Mo rí ìwé àkọsílẹ̀ ìtàn ìran àwọn tí ó kọ́ gòkè padà wá láti ìgbèkùn. Èyí ni ohun tí mo rí tí a kọ sínú ìwé náà.
5 E o meu Deus pôs no meu coração de reunir-me com os nobres, e os governantes, e o povo, para que eles pudessem ser considerados por genealogia. E achei um registro da genealogia dos que subiram primeiro, e nele achei escrito:
6 Èyí ni àwọn ènìyàn agbègbè náà tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá láti ìgbèkùn, àwọn tí Nebukadnessari ọba Babeli ti kó ní ìgbèkùn (wọ́n padà sí Jerusalẹmu àti Juda, olúkúlùkù sí ìlú u rẹ̀.
6 Estes são os filhos da província, que saíram do cativeiro, daqueles que haviam sido levados, os quais Nabucodonosor, o rei de Babilônia, havia levado consigo, e retornaram para Jerusalém e para Judá, cada um para a sua cidade;
7 Wọ́n jọ rìn wá pẹ̀lú u Serubbabeli, Jeṣua, Nehemiah, Asariah, Raamiah, Nahamani, Mordekai, Bilṣani, Misperi, Bigfai, Nehumu, àti Baanah).
7 que vieram com Zorobabel, Jesuá, Neemias, Azarias, Raamias, Naamani, Mardoqueu, Bilsã, Misperete, Bigvai, Neum e Baaná. O número, refiro-me dos homens do povo de Israel era esse:
8 àwọn ọmọ
8 Os filhos de Parós, dois mil cento e setenta e dois.
9 Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá (372)
9 Os filhos de Sefatias, trezentos e setenta e dois.
10 Arah jẹ́ ẹgbẹ̀tàléláàádọ́ta ó lé méjì (652)
10 Os filhos de Ará, seiscentos e cinquenta e dois.
11 Pahati-Moabu (láti ipasẹ̀ ọmọ Jeṣua àti Joabu) jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìnlá ó lé méjìdínlógún (2,818)
11 Os filhos de Paate-Moabe, dos filhos de Jesuá e Joabe, dois mil oitocentos e dezoito.
12 Elamu jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀fà ó lé mẹ́rin (1,254)
12 Os filhos de Elão, mil duzentos e cinquenta e quatro.
13 Sattu jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún (845)
13 Os filhos de Zatu, oitocentos e quarenta e cinco.
14 Sakkai jẹ́ òjìdínlẹ́gbẹ̀rin (760)
14 Os filhos de Zacai, setecentos e sessenta.
15 Binnui jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀ta ó lé mẹ́jọ (648)
15 Os filhos de Binui, seiscentos e quarenta e oito.
16 Bebai jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé méjìdínlọ́gbọ̀n (628)
16 Os filhos de Bebai, seiscentos e vinte e oito.
17 Asgadi jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó dín méjìdínlọ́gọ́rin (2,322)
17 Os filhos de Azgade, dois mil trezentos e vinte e dois.
18 Adonikami jẹ́ ọ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó lé méje (667)
18 Os filhos de Adonicão, seiscentos e sessenta e sete.
19 Bigfai jẹ́ ẹgbàá ó lé mẹ́tàdínláàádọ́rin (2,067)
19 Os filhos de Bigvai, dois mil e sessenta e sete.
20 Adini jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀ta ó lé márùn-ún (655)
20 Os filhos de Adim, seiscentos e cinquenta e cinco.
21 Ateri (láti ipasẹ̀ Hesekiah) jẹ́ méjìdínlọ́gọ́rùn-ún (98)
21 Os filhos de Ater, de Ezequias, noventa e oito.
22 Haṣumu jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó ó lé mẹ́jọ (328)
22 Os filhos de Hasum, trezentos e vinte e oito.
23 Besai jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó ó lé mẹ́rin (324)
23 Os filhos de Besai, trezentos e vinte e quatro.
24 Harifu jẹ́ méjìléláàádọ́fà (112)
24 Os filhos de Harife, cento e doze.
25 Gibeoni jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùn (95).
25 Os filhos de Gibeão, noventa e cinco.
26 Àwọn ọmọ
26 Os homens de Belém e de Netofa, cento e oitenta e oito.
27 Anatoti jẹ́ méjìdínláàádóje (128)
27 Os homens de Anatote, cento e vinte e oito.
28 Beti-Asmafeti jẹ́ méjìlélógójì (42)
28 Os homens de Bete-Azmavete, quarenta e dois.
29 Kiriati-Jearimu, Kefira, àti Beeroti jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó lé mẹ́ta (743)
29 Os homens de Quiriate-Jearim, Cefira e Beerote, setecentos e quarenta e três.
30 Rama àti Geba jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mọ́kànlélógún (621)
30 Os homens de Ramá e Geba, seiscentos e vinte e um.
31 Mikmasi jẹ́ méjìlélọ́gọ́fà (122)
31 Os homens de Micmás, cento e vinte e dois.
32 Beteli àti Ai jẹ́ mẹ́tàlélọ́gọ́fà (123)
32 Os homens de Betel e Ai, cento e vinte e três.
33 Nebo mìíràn jẹ́ méjìléláàádọ́ta (52)
33 Os homens doutra Nebo, cinquenta e dois.
34 Elamu mìíràn jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́rìnléláàádọ́ta (1,254)
34 Os filhos do outro Elão, mil duzentos e cinquenta e quatro.
35 Harimu jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó (320)
35 Os filhos de Harim, trezentos e vinte.
36 Jeriko jẹ́ ọ̀tàdínnírinwó ó lé márùn-ún (345).
36 Os filhos de Jericó, trezentos e quarenta e cinco.
37 Lodi, Hadidi, àti Ono jẹ́ ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rin ó lé ọ̀kan (721)
37 Os filhos de Lode, Hadide e Ono, setecentos e vinte e um.
38 Senaa jẹ́ ẹgbàajì ó dín àádọ́rin (3,930).
38 Os filhos de Senaá, três mil novecentos e trinta.
39 Àwọn àlùfáà:
39 Os sacerdotes: os filhos de Jedaías, da casa de Jesuá, novecentos e setenta e três.
40 Immeri jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀rún ó lé méjì (1,052)
40 Os filhos de Imer, mil e cinquenta e dois.
41 Paṣuri jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́tàdínláàádọ́ta (1,247)
41 Os filhos de Pasur, mil duzentos e quarenta e sete.
42 Harimu jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó lé mẹ́tàdínlógún (1,017).
42 Os filhos de Harim, mil e dezessete.
43 Àwọn ọmọ Lefi:
43 Os levitas: os filhos de Jesuá, de Cadmiel, e os filhos de Hodeva, setenta e quatro.
44 Àwọn akọrin:
44 Os cantores: os filhos de Asafe, cento e quarenta e oito.
45 Àwọn aṣọ́nà:
45 Os porteiros: os filhos de Salum, os filhos de Ater, os filhos de Talmom, os filhos de Acube, os filhos de Hatita, os filhos de Sobai, cento e trinta e oito.
46 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili.
46 Os netineus: os filhos de Zia, os filhos de Hasufa, os filhos de Tabaote,
47 Kerosi, Sia, Padoni,
47 os filhos de Queros, os filhos de Sia, os filhos de Padom,
48 Lebana, Hagaba, Ṣalmai,
48 os filhos de Lebana, os filhos de Hagaba, os filhos de Salmai,
49 Hanani, Giddeli, Gahari,
49 os filhos de Hanã, os filhos de Gidel, os filhos de Gaar,
50 Reaiah, Resini, Nekoda,
50 os filhos de Reaías, os filhos de Rezim, os filhos de Necoda,
51 Gassamu, Ussa, Pasea,
51 os filhos de Gazão, os filhos de Uzá, os filhos de Paseia,
52 Besai, Mehuni, Nefisimu,
52 os filhos de Besai, os filhos de Meunim, os filhos de Nefusesim,
53 Bakbu, Hakufa, Harhuri,
53 os filhos de Baquebuque, os filhos de Hacufa, os filhos de Harur,
54 Basluti, Mehida, Harṣa,
54 os filhos de Bazlite, os filhos de Meida, os filhos de Harsa,
55 Barkosi, Sisera, Tema,
55 os filhos de Barcos, os filhos de Sísera, os filhos de Tama,
56 Nesia, àti Hatifa.
56 os filhos de Nesias, os filhos de Hatifa.
57 Àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni:
57 Os filhos dos servos de Salomão: os filhos de Sotai, os filhos de Soferete, os filhos de Perida,
58 Jaala, Darkoni, Giddeli,
58 os filhos de Jaala, os filhos de Darcom, os filhos de Gidel,
59 Ṣefatia, Hattili,
59 os filhos de Sefatias, os filhos de Hatil, os filhos de Poquerete-Hazebaim, os filhos de Amom.
60 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ọmọ ìránṣẹ́ Solomoni jẹ́ irinwó ó dín mẹ́jọ (392).
60 Todos os netineus e os filhos dos servos de Salomão: eram trezentos e noventa e dois.
61 Àwọn wọ̀nyí gòkè wá láti àwọn ìlú ti Teli-Mela, Teli-Harṣa, Kerubu, Addoni àti Immeri, ṣùgbọ́n wọn kò lè sọ pẹ̀lú ìdánilójú pé ìdílé àwọn wá láti ara ìran ẹ̀yà Israẹli.
61 E estes foram os que subiram de Tel-Melá, Tel-Harsa, Querube, Adom e Imer; mas eles não conseguiram apresentar a casa do seu pai, nem a sua semente, se eram de Israel.
62 Àwọn ọmọ
62 Os filhos de Delaías, os filhos de Tobias, os filhos de Necoda, seiscentos e quarenta e dois.
63 Lára àwọn àlùfáà ni:
63 E dos sacerdotes: os filhos de Habaías, os filhos de Coz, os filhos de Barzilai, o qual tomou uma das filhas de Barzilai, o gileadita, como esposa, e foi chamado segundo o seu nome.
64 Àwọn wọ̀nyí wá àkọsílẹ̀ orúkọ ìran wọn, ṣùgbọ́n wọn kò rí í níbẹ̀, fún ìdí èyí, a yọ wọ́n kúrò nínú àwọn tí ń ṣiṣẹ́ àlùfáà gẹ́gẹ́ bí aláìmọ́.
64 Estes buscaram o seu registro entre aqueles que foram considerados pela genealogia, mas não foram achados; por isso foram eles, como imundos, e excluídos do sacerdócio.
65 Baálẹ̀ sọ fún wọn nítorí náà pé wọn kò gbọdọ̀ kópa nínú jíjẹ oúnjẹ mímọ́ títí tí àlùfáà tí yóò wá tí ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú Urimu àti Tumimu yóò fi dé.
65 E o tirsata disse-lhes para que eles não comessem das coisas santíssimas, até que ali se pusesse de pé um sacerdote com Urim e com Tumim.
66 Gbogbo ìjọ ènìyàn náà jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lé òjìdínnírinwó (42,360),
66 E toda congregação junta eram de quarenta e dois mil trezentos e sessenta,
67 yàtọ̀ sí àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin tí wọ́n jẹ́ ẹgbẹ̀ta dín lẹ́gbàárin ó dín ẹ̀tàlélọ́gọ́ta (7,337); wọ́n sì tún ní àwọn akọrin ọkùnrin àti obìnrin tí wọ́n jẹ́ òjìlúgba ó lé márùn-ún (245).
67 fora os seus servos e as suas servas, dos quais havia sete mil trezentos e trinta e sete; e eles tinham duzentos e quarenta e cinco cantores e cantoras.
68 Ẹṣin wọn jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́rin (736), ìbákasẹ wọn jẹ́ òjìlúgba ó dín márùn-ún (245);
68 Os seus cavalos, setecentos e trinta e seis; as suas mulas, duzentos e quarenta e cinco;
69 ìbákasẹ wọn jẹ́ òjìlénírinwó ó dín márùn-ún (435); kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọ́n jẹ́ ẹgbẹ̀rìnlélọ́gbọ̀n ó dín ọgọ́rin (6,720).
69 os seus camelos, quatrocentos e trinta e cinco; e seis mil setecentos e vinte jumentos.
70 Díẹ̀ lára àwọn olórí ìdílé náà kópa nínú ṣíṣe iṣẹ́ náà. Baálẹ̀ fún ilé ìṣúra ní ẹgbẹ̀rún (1,000) dariki wúrà, àádọ́ta àwo koto àti ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀ta lé mẹ́wàá (530) ẹ̀wù fún àwọn àlùfáà.
70 E alguns dos chefes dos pais doaram para a obra. O tirsata deu ao tesouro mil dáricos de ouro, cinquenta bacias, quinhentas e trinta vestes sacerdotais.
71 Díẹ̀ lára àwọn olórí ìdílé fún ilé ìṣúra ní ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) dariki wúrà àti ẹgbọ̀kànlá (2,200) mina fàdákà.
71 E alguns dos chefes dos pais doaram ao tesouro da obra vinte mil dáricos de ouro, e duas mil e duzentas libras de prata.
72 Àròpọ̀ gbogbo ohun tí àwọn ènìyàn tókù fi sílẹ̀ jẹ́ ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) dariki wúrà, ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) mina fàdákà àti ẹẹ́tàdínláàdọ́rin ẹ̀wù fún àwọn àlùfáà.
72 E aquilo que o restante do povo doou foi vinte mil dáricos de ouro, e duas mil libras de prata, e sessenta e sete vestes sacerdotais.
73 Àwọn àlùfáà, àwọn Lefi, àwọn aṣọ́bodè, àwọn akọrin, àwọn ènìyàn díẹ̀, àwọn ìránṣẹ́ ilé Ọlọ́run, àti gbogbo ènìyàn Israẹli wà ní ìlú wọn.
73 Assim, os sacerdotes e os levitas, e os porteiros, e os cantores, e alguns do povo, e os netineus, e todo o Israel, habitaram nas suas cidades. E quando o sétimo mês chegou, os filhos de Israel estavam nas suas cidades.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Neemias 7, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.