Neemias 7

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs ARIB

Sair da comparação
ARIB Almeida Revisada Imprensa Bíblica
1 Lẹ́yìn ìgbà tí a tún odi mọ tán tí mo sì ri àwọn ìlẹ̀kùn sí ààyè wọn, a sì yan àwọn aṣọ́bodè, àwọn akọrin àti àwọn Lefi.
1 Ora, depois que o muro foi edificado, tendo eu assentado as portas, e havendo sido designados os porteiros, os cantores e os levitas,
2 Mo fún Hanani arákùnrin mi pẹ̀lú Hananiah olórí ilé ìṣọ́ ní àṣẹ lórí Jerusalẹmu, nítorí tí ó jẹ́ ènìyàn olóòtítọ́, ó sì bẹ̀rù Ọlọ́run jù bí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ti ṣe lọ.
2 pus Hanâni, meu irmão, e Hananias, governador do castelo, sobre Jerusalém; pois ele era homem fiel e temente a Deus, mais do que muitos;
3 Mo sọ fún wọn pé, “A kò gbọdọ̀ ṣí ìlẹ̀kùn Jerusalẹmu títí oòrùn yóò fi mú. Nígbà tí àwọn aṣọ́bodè bá sì wà lẹ́nu iṣẹ́, jẹ́ kí wọn ti ìlẹ̀kùn kí wọn sì há wọn. Bákan náà, yàn nínú àwọn tí ń gbé Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́. Àwọn mìíràn níbi tí a pín wọn sí àti àwọn mìíràn ní tòsí ilé e wọn.”
3 e eu lhes disse: Não se abram as portas de Jerusalém até que o sol aqueça; e enquanto os guardas estiverem nos postos se fechem e se tranquem as portas; e designei dentre os moradores de Jerusalém guardas, cada um por seu turno, e cada um diante da sua casa.
4 Ìlú náà tóbi ó sì ní ààyè, ṣùgbọ́n ènìyàn inú rẹ̀ kéré, a kò sì tí ì tún àwọn ilé inú rẹ̀ kọ́.
4 Ora, a cidade era larga e grande, mas o povo dentro dela era pouco, e ainda as casa não estavam edificadas.
5 Nígbà náà ni Ọlọ́run mi fi sí mi ní ọkàn láti kó àwọn ọlọ́lá, àwọn ìjòyè, àti àwọn ènìyàn jọ fún ìforúkọsílẹ̀ ní ìdílé ìdílé. Mo rí ìwé àkọsílẹ̀ ìtàn ìran àwọn tí ó kọ́ gòkè padà wá láti ìgbèkùn. Èyí ni ohun tí mo rí tí a kọ sínú ìwé náà.
5 Então o meu Deus me pôs no coração que ajuntasse os nobres, os magistrados e o povo, para registrar as genealogias. E achei o livro da genealogia dos que tinham subido primeiro e achei escrito nele o seguinte:
6 Èyí ni àwọn ènìyàn agbègbè náà tí wọ́n sọ̀kalẹ̀ wá láti ìgbèkùn, àwọn tí Nebukadnessari ọba Babeli ti kó ní ìgbèkùn (wọ́n padà sí Jerusalẹmu àti Juda, olúkúlùkù sí ìlú u rẹ̀.
6 Este são os filhos da província que subiram do cativeiro dentre os exilados, que Nabucodonosor, rei da Babilônia, transportara e que voltaram para Jerusalém e para Judá, cada um para a sua cidade,
7 Wọ́n jọ rìn wá pẹ̀lú u Serubbabeli, Jeṣua, Nehemiah, Asariah, Raamiah, Nahamani, Mordekai, Bilṣani, Misperi, Bigfai, Nehumu, àti Baanah).
7 os quais vieram com Zorobabel, Jesuá, Neemias, Azarias, Raamias, Naamâni, Mordecai, Bilsã, Misperete, Bigvai, Neum e Baaná. Este é o número dos homens do povo de Israel:
8 àwọn ọmọ
8 foram os filhos de Parós, dois mil cento e setenta e dois;
9 Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá (372)
9 os filhos de Sefatias, trezentos e setenta e dois;
10 Arah jẹ́ ẹgbẹ̀tàléláàádọ́ta ó lé méjì (652)
10 os filhos de Ará, seiscentos e cinqüenta e dois;
11 Pahati-Moabu (láti ipasẹ̀ ọmọ Jeṣua àti Joabu) jẹ́ ẹgbàá mẹ́rìnlá ó lé méjìdínlógún (2,818)
11 os filhos de Paate-Moabe, dos filhos de Jesuá e de Joabe, dois mil oitocentos e dezoito;
12 Elamu jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀fà ó lé mẹ́rin (1,254)
12 os filhos de Elão, mil duzentos e cinqüenta e quatro;
13 Sattu jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún (845)
13 os filhos de Zatu, oitocentos e quarenta e cinco;
14 Sakkai jẹ́ òjìdínlẹ́gbẹ̀rin (760)
14 os filhos de Zacai, setecentos e sessenta;
15 Binnui jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀ta ó lé mẹ́jọ (648)
15 os filhos de Binuí, seiscentos e quarenta e oito;
16 Bebai jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé méjìdínlọ́gbọ̀n (628)
16 os filhos de Bebai, seiscentos e vinte e oito;
17 Asgadi jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó dín méjìdínlọ́gọ́rin (2,322)
17 os filhos de Azgade, dois mil trezentos e vinte e dois;
18 Adonikami jẹ́ ọ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó lé méje (667)
18 os filhos de Adonicão, seiscentos e sessenta e sete;
19 Bigfai jẹ́ ẹgbàá ó lé mẹ́tàdínláàádọ́rin (2,067)
19 os filhos de Bigvai, dois mil e sessenta e sete;
20 Adini jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀ta ó lé márùn-ún (655)
20 os filhos de Adim, seiscentos e cinqüenta e cinco;
21 Ateri (láti ipasẹ̀ Hesekiah) jẹ́ méjìdínlọ́gọ́rùn-ún (98)
21 os filhos de Ater, de Ezequias, noventa e oito;
22 Haṣumu jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó ó lé mẹ́jọ (328)
22 os filhos de Hasum, trezentos e vinte e oito;
23 Besai jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó ó lé mẹ́rin (324)
23 os filhos de Bezai, trezentos e vinte e quatro;
24 Harifu jẹ́ méjìléláàádọ́fà (112)
24 os filhos de Harife, cento e doze;
25 Gibeoni jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùn (95).
25 os filhos de Gibeão, noventa e cinco;
26 Àwọn ọmọ
26 os filhos de Belém e de Netofá, cento e oitenta e oito;
27 Anatoti jẹ́ méjìdínláàádóje (128)
27 os homens de Anatote, cento e vinte e oito;
28 Beti-Asmafeti jẹ́ méjìlélógójì (42)
28 os homens de Bete-Azmavete, quarenta e dois;
29 Kiriati-Jearimu, Kefira, àti Beeroti jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó lé mẹ́ta (743)
29 os homens de Quiriate-Jeriam, de Cefira, e de Beerote, setecentos e quarenta e três;
30 Rama àti Geba jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mọ́kànlélógún (621)
30 os homens de Ramá e Gaba, seiscentos e vinte e um;
31 Mikmasi jẹ́ méjìlélọ́gọ́fà (122)
31 os homens de Micmás, cento e vinte e dois;
32 Beteli àti Ai jẹ́ mẹ́tàlélọ́gọ́fà (123)
32 os homens de Betel e Ai, cento e vinte e três;
33 Nebo mìíràn jẹ́ méjìléláàádọ́ta (52)
33 os homens do outro Nebo, cinqüenta e dois;
34 Elamu mìíràn jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́rìnléláàádọ́ta (1,254)
34 os filhos do outro Elão, mil duzentos e cinqüenta e quatro;
35 Harimu jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó (320)
35 os filhos de Harim, trezentos e vinte;
36 Jeriko jẹ́ ọ̀tàdínnírinwó ó lé márùn-ún (345).
36 os filhos de Jericó, trezentos e quarenta e cinco;
37 Lodi, Hadidi, àti Ono jẹ́ ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rin ó lé ọ̀kan (721)
37 os filhos de Lode, de hadide e de Ono, setecentos e vinte e um;
38 Senaa jẹ́ ẹgbàajì ó dín àádọ́rin (3,930).
38 os filhos de Senaá, três mil novecentos e trinta.
39 Àwọn àlùfáà:
39 Os sacerdotes: os filhos de Jedaías, da casa de Jesuá, novecentos e setenta e três;
40 Immeri jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀rún ó lé méjì (1,052)
40 os filhos de Imer, mil e cinqüenta e dois;
41 Paṣuri jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́tàdínláàádọ́ta (1,247)
41 os filhos de Pasur, mil duzentos e quarenta e sete;
42 Harimu jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó lé mẹ́tàdínlógún (1,017).
42 os filhos de Harim, mil e dezessete;
43 Àwọn ọmọ Lefi:
43 Os levitas: os filhos de Jesuá, de Cadmiel, dos filhos de Hodevá, setenta e quatro.
44 Àwọn akọrin:
44 Os cantores: os filhos de Asafe, cento e quarenta e oito.
45 Àwọn aṣọ́nà:
45 Os porteiros: os filhos de Salum, os filhos de Ater, os filhos de Talmom, os filhos de Acube, os filhos de Hatita, os filhos de Sobai, cento e trinta e oito.
46 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili.
46 Os netinis: os filhos de Ziá, os filhos de Hasufa, os filhos de Tabaote,
47 Kerosi, Sia, Padoni,
47 os filhos de Querós, os filhos de Siá, os filhos de Padom,
48 Lebana, Hagaba, Ṣalmai,
48 os filhos de Lebana, os filhos de Hagaba, os filhos de Salmai,
49 Hanani, Giddeli, Gahari,
49 os filhos de Hanã, os filhos de Gidel, os filhos de Gaar,
50 Reaiah, Resini, Nekoda,
50 os filhos de Recaías, os filhos de Rezim, os filhos de Necoda,
51 Gassamu, Ussa, Pasea,
51 os filhos de Gazão, os filhos de Uzá, os filhos de Paséia,
52 Besai, Mehuni, Nefisimu,
52 os filhos de Besai, os filhos de Meunim, os filhos de Nefusesim,
53 Bakbu, Hakufa, Harhuri,
53 os filhos de Baquebuque, os filhos de Hacufa, os filhos de Hacur,
54 Basluti, Mehida, Harṣa,
54 os filhos de Bazlite, os filhos de Meída, os filhos de Harsa,
55 Barkosi, Sisera, Tema,
55 os filhos de Barcos, os filhos de Sísera, os filhos de Tamá,
56 Nesia, àti Hatifa.
56 os filhos de Nezias, os filhos de Hatifa,
57 Àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni:
57 os filhos dos servos de Salomão: os filhos de Sotai, os filhos de Soforete, os filhos de Perida,
58 Jaala, Darkoni, Giddeli,
58 os filhos de Jaala, os filhos de Darcom, os filhos de Gidel,
59 Ṣefatia, Hattili,
59 os filhos de Sefatias, os filhos de Hatil, os filhos de Paquerete-Hazebaim e os filhos de Amom.
60 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ọmọ ìránṣẹ́ Solomoni jẹ́ irinwó ó dín mẹ́jọ (392).
60 Todos os netinins e os filhos dos servos de Salomão, eram trezentos e noventa e dois.
61 Àwọn wọ̀nyí gòkè wá láti àwọn ìlú ti Teli-Mela, Teli-Harṣa, Kerubu, Addoni àti Immeri, ṣùgbọ́n wọn kò lè sọ pẹ̀lú ìdánilójú pé ìdílé àwọn wá láti ara ìran ẹ̀yà Israẹli.
61 Estes foram os que subiram de Tel-Mela, Tel-Harsa, Querube, Adom, e Imer; porém não puderam provar que as suas casas paternas e as sua linhagem eram de Israel:
62 Àwọn ọmọ
62 os filhos de Dalaías, os filhos de Tobias, os filhos de Necoda, seiscentos e quarenta e dois.
63 Lára àwọn àlùfáà ni:
63 E dos sacerdotes: os filhos de Hobaías, os filhos Hacoz, os filhos de Barzilai, que tomara por mulher uma das filhas Barzilai, o gileadita, e que foi chamado do seu nome.
64 Àwọn wọ̀nyí wá àkọsílẹ̀ orúkọ ìran wọn, ṣùgbọ́n wọn kò rí í níbẹ̀, fún ìdí èyí, a yọ wọ́n kúrò nínú àwọn tí ń ṣiṣẹ́ àlùfáà gẹ́gẹ́ bí aláìmọ́.
64 Estes buscaram o seu registro entre os arrolados nos registros genealógicos, mas não foi encontrado; pelo que, tidos por imundos, foram excluídos do sacerdócio.
65 Baálẹ̀ sọ fún wọn nítorí náà pé wọn kò gbọdọ̀ kópa nínú jíjẹ oúnjẹ mímọ́ títí tí àlùfáà tí yóò wá tí ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú Urimu àti Tumimu yóò fi dé.
65 E o governador lhes disse que não comesse das coisas sagradas, até que se levantasse um sacerdote com Urim e Tumim.
66 Gbogbo ìjọ ènìyàn náà jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lé òjìdínnírinwó (42,360),
66 Toda esta congregação junta somava quarenta e dois mil trezentos e sessenta;
67 yàtọ̀ sí àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin tí wọ́n jẹ́ ẹgbẹ̀ta dín lẹ́gbàárin ó dín ẹ̀tàlélọ́gọ́ta (7,337); wọ́n sì tún ní àwọn akọrin ọkùnrin àti obìnrin tí wọ́n jẹ́ òjìlúgba ó lé márùn-ún (245).
67 afora os seus servos e as suas servas, que foram sete mil trezentos e trinta e sete; e tinham duzentos e quarenta e cinco cantores e cantoras.
68 Ẹṣin wọn jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́rin (736), ìbákasẹ wọn jẹ́ òjìlúgba ó dín márùn-ún (245);
68 Os seus cavalos foram setecentos e trinta e seis; os seus mulos, duzentos e quarenta e cinco;
69 ìbákasẹ wọn jẹ́ òjìlénírinwó ó dín márùn-ún (435); kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọ́n jẹ́ ẹgbẹ̀rìnlélọ́gbọ̀n ó dín ọgọ́rin (6,720).
69 os seus camelos, quatrocentos e trinta e cinco; e os seus jumentos, seis mil setecentos e vinte.
70 Díẹ̀ lára àwọn olórí ìdílé náà kópa nínú ṣíṣe iṣẹ́ náà. Baálẹ̀ fún ilé ìṣúra ní ẹgbẹ̀rún (1,000) dariki wúrà, àádọ́ta àwo koto àti ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀ta lé mẹ́wàá (530) ẹ̀wù fún àwọn àlùfáà.
70 Ora, alguns dos cabeças das casas paternas contribuíram para a obra. O governador deu para a tesouraria mil dários de ouro, cinqüenta bacias, e quinhentas e trinta vestes sacerdotais.
71 Díẹ̀ lára àwọn olórí ìdílé fún ilé ìṣúra ní ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) dariki wúrà àti ẹgbọ̀kànlá (2,200) mina fàdákà.
71 E alguns dos cabeças das casas paternas deram para a tesouraria da obra vinte mil dáricos de ouro, e duas mil e duzentas minas de prata.
72 Àròpọ̀ gbogbo ohun tí àwọn ènìyàn tókù fi sílẹ̀ jẹ́ ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) dariki wúrà, ẹgbẹ̀rún méjì (2,000) mina fàdákà àti ẹẹ́tàdínláàdọ́rin ẹ̀wù fún àwọn àlùfáà.
72 O que o resto do povo deu foram vinte mil dáricos de ouro, duas mil minas de prata, e sessenta e sete vestes sacerdotais.
73 Àwọn àlùfáà, àwọn Lefi, àwọn aṣọ́bodè, àwọn akọrin, àwọn ènìyàn díẹ̀, àwọn ìránṣẹ́ ilé Ọlọ́run, àti gbogbo ènìyàn Israẹli wà ní ìlú wọn.
73 Os sacerdotes, os levitas, os porteiros, os cantores, alguns dentre o povo, os netinins e todo o Israel habitaram nas suas cidades. Quando chegou o sétimo mês, já se achavam os filhos de Israel nas suas cidades.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Neemias 7, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.