Josué 19

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH

Sair da comparação
NTLH Nova Tradução na Linguagem de Hoje 2000
1 Kèké kejì jáde fún ẹ̀yà Simeoni, ní agbo ilé, ní agbo ilé. Ìní wọn sì wà ní àárín ilẹ̀ Juda.
1 A segunda distribuição de terras foi feita para as famílias da tribo de Simeão. A sua parte ficava no meio das terras da tribo de Judá.
2 Lára ìpín wọn ní:
2 Eram da tribo de Simeão as cidades de Berseba, Seba, Molada,
3 Hasari-Ṣuali, Bala, Esemu,
3 Hazar-Sual, Balá, Ezém,
4 Eltoladi, Betuli, Horma,
4 Eltolade, Betul, Horma,
5 Siklagi, Beti-Markaboti, Hasari Susa,
5 Ziclague, Bete-Marcabote, Hazar-Susa,
6 Beti-Lebaoti àti Ṣarueli, ìlú wọn jẹ́ mẹ́tàlá àti ìletò wọn.
6 Bete-Lebaote e Saruém. Ao todo treze cidades, mais os povoados vizinhos.
7 Aini, Rimoni, Eteri àti Aṣani, ìlú wọn jẹ́ mẹ́rin àti ìletò wọn,
7 Também eram dessa tribo Aim, Rimom, Eter e Asã. Ao todo quatro cidades com os seus povoados.
8 àti gbogbo àwọn agbègbè ìlú wọ̀nyí títí dé Baalati-Beeri (Rama ní gúúsù).
8 Pertenciam ainda à tribo de Simeão todos os povoados vizinhos dessas cidades até Baalate-Ber, isto é, Ramá do Sul. Estas foram as terras que as famílias da tribo de Simeão receberam como sua propriedade.
9 A mú ogún ìní àwọn ọmọ Simeoni láti ìpín Juda, nítorí ìpín Juda pọ̀ ju èyí tí wọ́n nílò lọ. Báyìí ni àwọn ọmọ Simeoni gba ìní wọn ní àárín ilẹ̀ Juda.
9 A parte da tribo de Simeão foi tirada das terras de Judá. As terras dadas a Judá eram grandes demais para essa tribo, de modo que a de Simeão recebeu parte delas.
10 Kèké kẹta jáde fún Sebuluni, ní agbo ilé ní agbo ilé
10 A terceira distribuição de terras foi feita para as famílias da tribo de Zebulom. Elas receberam terras que iam até Saride.
11 Ó sì lọ sí ìwọ̀-oòrùn ní Marala, ó sì dé Dabbeṣeti, ó sì lọ títí dé odo ní ẹ̀bá Jokneamu.
11 A sua divisa subia na direção oeste até Marala, passava por Dabasete e chegava ao riacho que fica a leste de Jocneão.
12 Ó sì yípadà sí ìlà-oòrùn láti Saridi sí ìhà ìlà-oòrùn dé ilẹ̀ Kisiloti-Tabori, ó sì lọ sí Daberati, ó sì gòkè lọ sí Jafia.
12 Do outro lado de Saride, seguia para o leste até a divisa com Quislote-Tabor, passava por Daberate e, subindo, chegava até Jafia.
13 Nígbà náà ní o lọ sí ìhà ìlà-oòrùn lọ sí Gati-Heferi àti Eti-Kaṣini, ó sì jáde ní Rimoni, ó sì yí sí ìhà Nea.
13 Continuava na direção leste até Gate-Hefer e Ete-Cazim, virando para o lado de Neia, pelo caminho de Rimom.
14 Ní ibẹ̀, ààlà sì yíká ní ìhà àríwá lọ sí Hnatoni ó sì pín ní àfonífojì Ifita-Eli.
14 No Norte a divisa virava para o lado de Hanatom, terminando no vale de Iftael.
15 Lára wọn ni Katati, Nahalali, Ṣimroni, Idala àti Bẹtilẹhẹmu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlá àti ìletò wọn.
15 Das terras de Zebulom também faziam parte Catate, Naalal, Sinrom, Idala e Belém. Ao todo doze cidades, mais os seus povoados.
16 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní Sebuluni, ní agbo ilé agbo ilé.
16 Essas cidades e povoados estavam nas terras que as famílias da tribo de Zebulom receberam como sua propriedade.
17 Kèké kẹrin jáde fún Isakari, agbo ilé ní agbo ilé.
17 A quarta distribuição de terras foi feita para as famílias da tribo de Issacar.
18 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí:
18 As suas terras incluíam as cidades de Jezreel, Quesulote, Suném,
19 Hafraimu, Ṣihoni, Anaharati,
19 Hafaraim, Seom, Anacarate,
20 Rabiti, Kiṣioni, Ebesi,
20 Rabite, Quisião, Ebes,
21 Remeti, Eni-Gannimu, Eni-Hada àti Beti-Pasesi.
21 Remete, En-Ganim, En-Hada e Bete-Pasês.
22 Ààlà náà sì dé Tabori, Ṣahasuma, àti Beti-Ṣemeṣi, ó sì pin ní Jordani.
22 A divisa passava por Tabor, Saazima e Bete-Semes, terminando no rio Jordão. Faziam parte das terras de Issacar dezesseis cidades, mais os seus povoados.
23 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní ẹ̀yà Isakari, ní agbo ilé agbo ilé.
23 Essas cidades e os seus povoados estavam nas terras que as famílias da tribo de Issacar receberam como sua propriedade.
24 Kèké karùn-ún jáde fún ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
24 A quinta distribuição de terras foi feita para as famílias da tribo de Aser.
25 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí:
25 Essas terras incluíam as cidades de Helcate, Hali, Betém, Acsafe,
26 Allameleki, Amadi, àti Miṣali. Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ààlà náà dé Karmeli àti Ṣihori-Libinati.
26 Alameleque, Amade e Misal. No lado oeste a divisa chegava ao monte Carmelo e Sior-Libnate.
27 Nígbà náà ni o yí sí ìhà ìlà-oòrùn Beti-Dagoni, dé Sebuluni àti àfonífojì Ifita-Eli, ó sì lọ sí àríwá sí Beti-Emeki àti Neieli, ó sì kọjá lọ sí Kabulu ní apá òsì.
27 Depois virava para o leste até Bete-Dagom, passava por Zebulom e pelo vale de Iftael e ia para o norte até Bete-Emeque e Neiel. Continuava para o norte até as cidades de Cabul,
28 Ó sì lọ sí Abdoni, Rehobu, Hammoni àti Kana títí dé Sidoni ńlá.
28 Ebrom, Reobe, Hamom e Caná, chegando até a grande Sidom.
29 Ààlà náà sì tẹ̀ sí ìhà Rama, ó sì lọ sí ìlú olódi Tire, ó sì yà sí Hosa, ó sì jáde ní Òkun Ńlá ní ilẹ̀ Aksibu,
29 A divisa então virava para o lado de Ramá, chegando a Tiro, a cidade cercada de muralhas. Daí virava para o lado de Hosa e terminava no mar Mediterrâneo. Das terras de Aser também faziam parte Maalabe, Aczibe,
30 Uma, Afeki àti Rehobu.
30 Umá, Afeca e Reobe. Ao todo vinte e duas cidades, mais os seus povoados.
31 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
31 Essas cidades e os seus povoados estavam nas terras que as famílias da tribo de Aser receberam como sua propriedade.
32 Ìpín kẹfà jáde fún Naftali, agbo ilé ní agbo ilé,
32 A sexta distribuição de terras foi feita para as famílias da tribo de Naftali.
33 ààlà wọn lọ láti Helefi àti igi ńlá ní Saananimu nímù; kọjá lọ sí Adami Nekebu àti Jabneeli dé Lakkumu, ó sì pín ní Jordani.
33 A sua divisa começava em Helefe, desde o carvalho de Zaananim, e ia de Adami-Nequebe e Jabneel até Lacum, terminando no rio Jordão.
34 Ààlà náà gba ìhà ìwọ̀-oòrùn lọ sí Asnoti-Tabori ó sì jáde ní Hukoki. Ó sì dé Sebuluni, ní ìhà gúúsù Aṣeri ní ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Juda ní Jordani ní ìhà ìlà-oòrùn.
34 A divisa virava para o oeste e ia até Aznote-Tabor; daí seguia até Hucoque, chegando até Zebulom ao sul, até Aser a oeste e até Judá a leste, no rio Jordão.
35 Àwọn ìlú olódi sì Siddimu, Seri, Hamati, Rakàti, Kinnereti,
35 As cidades protegidas por muralhas eram Zidim, Zer, Hamate, Racate, Quinerete,
36 Adama, Rama Hasori,
36 Adamá, Ramá, Hazor,
37 Kedeṣi, Edrei, Eni-Aṣọri,
37 Quedes, Edrei, En-Hazor,
38 Ironi, Migdali-Eli, Horemu, Beti-Anati àti Beti-Ṣemeṣi.
38 Irom, Migdalel, Horém, Bete-Anate e Bete-Semes. Ao todo dezenove cidades, mais os seus povoados.
39 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Naftali, ní agbo ilé sí agbo ilé.
39 Essas cidades e os seus povoados estavam nas terras que as famílias da tribo de Naftali receberam como sua propriedade.
40 Ìbò kéje jáde fún ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé ní agbo ilé.
40 A sétima distribuição de terras foi feita para as famílias da tribo de Dã.
41 Ilẹ̀ ìní wọn nìwọ̀nyí:
41 As suas terras incluíam as cidades de Zora, Estaol, Ir-Semes,
42 Ṣaalabini, Aijaloni, Itila,
42 Saalabim, Aijalom, Itla,
43 Eloni, Timna, Ekroni,
43 Elom, Timna, Ecrom,
44 Elteke, Gibetoni, Baalati,
44 Elteque, Gibetom, Baalate,
45 Jehudu, Bene-Beraki, Gati-Rimoni,
45 Jeúde, Benê-Beraque, Gate-Rimom,
46 Me Jakoni àti Rakkoni, pẹ̀lú ilẹ̀ tí ó kọjú sí Joppa.
46 Me-Jarcom, Racom e as terras que ficam em frente da cidade de Jope.
47 (Ṣùgbọ́n àwọn ará Dani ní ìṣòro láti gba ilẹ̀ ìní wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gòkè lọ, wọ́n sì kọlu Leṣemu, wọ́n sì gbà á, wọ́n sì fi idà kọlù ú, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀. Wọ́n sì ń gbé ní Leṣemu, wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Dani orúkọ baba ńlá wọn).
47 Quando os descendentes de Dã perderam as suas terras, eles foram a Laís e a atacaram. Tomaram a cidade e mataram os seus moradores. Então tomaram posse da terra e passaram a morar nela. Mudaram o nome da cidade de Laís para Dã, que era o nome do fundador da tribo.
48 Àwọn ìlú wọ́n yí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé agbo ilé.
48 Essas cidades e os seus povoados estavam nas terras que as famílias da tribo de Dã receberam como sua propriedade.
49 Nígbà tí wọ́n ti parí pínpín ilẹ̀ náà ní ìpín ti olúkúlùkù, àwọn ará Israẹli fún Joṣua ọmọ Nuni ní ìní ní àárín wọn,
49 Quando os israelitas acabaram de fazer a divisão da terra, deram a Josué, filho de Num, uma parte para ser sua propriedade.
50 bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n fún un ni ìlú tí ó béèrè fún, Timnati Serah ní ìlú òkè Efraimu. Ó sì kọ́ ìlú náà, ó sì ń gbé ibẹ̀.
50 Como o Senhor tinha ordenado, deram a Josué a cidade que ele havia pedido. Essa cidade ficava na região montanhosa de Efraim e se chamava Timnate-Sera. Josué construiu a cidade de novo e passou a morar nela.
51 Wọ̀nyí ni àwọn ilẹ̀ tí Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti àwọn olórí ẹ̀yà agbo ilé Israẹli fi ìbò pín ní Ṣilo ní iwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Báyìí ni wọ́n parí pínpín ilẹ̀ náà.
51 O sacerdote Eleazar, Josué e os chefes das famílias das tribos de Israel fizeram a divisão da terra. Para fazerem essa divisão, consultaram o Senhor , por sorteio , na entrada da Tenda Sagrada , em Siló. E assim acabaram de repartir a terra.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Josué 19, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.