Josué 19

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NAA

Sair da comparação
NAA Nova Almeida Atualizada 2017
1 Kèké kejì jáde fún ẹ̀yà Simeoni, ní agbo ilé, ní agbo ilé. Ìní wọn sì wà ní àárín ilẹ̀ Juda.
1 Saiu a segunda sorte a Simeão, à tribo dos filhos de Simeão, segundo as suas famílias, e a herança deles ficava no meio da herança dos filhos de Judá.
2 Lára ìpín wọn ní:
2 Na herança receberam Berseba, Seba, Molada,
3 Hasari-Ṣuali, Bala, Esemu,
3 Hazar-Sual, Balá, Ezém,
4 Eltoladi, Betuli, Horma,
4 Eltolade, Betul, Horma,
5 Siklagi, Beti-Markaboti, Hasari Susa,
5 Ziclague, Bete-Marcabote, Hazar-Susa,
6 Beti-Lebaoti àti Ṣarueli, ìlú wọn jẹ́ mẹ́tàlá àti ìletò wọn.
6 Bete-Lebaote e Saruém. Ao todo, treze cidades com as suas aldeias.
7 Aini, Rimoni, Eteri àti Aṣani, ìlú wọn jẹ́ mẹ́rin àti ìletò wọn,
7 Aim, Rimom, Eter e Asã; ao todo, quatro cidades com as suas aldeias.
8 àti gbogbo àwọn agbègbè ìlú wọ̀nyí títí dé Baalati-Beeri (Rama ní gúúsù).
8 E todas as aldeias que havia ao redor destas cidades, até Baalate-Ber, que é Ramá do Neguebe. Esta era a herança da tribo dos filhos de Simeão, segundo as suas famílias.
9 A mú ogún ìní àwọn ọmọ Simeoni láti ìpín Juda, nítorí ìpín Juda pọ̀ ju èyí tí wọ́n nílò lọ. Báyìí ni àwọn ọmọ Simeoni gba ìní wọn ní àárín ilẹ̀ Juda.
9 A herança dos filhos de Simeão foi tirada da porção dos filhos de Judá, pois a herança destes era demasiadamente grande para eles. Por isso os filhos de Simeão receberam a sua herança no meio dos filhos de Judá.
10 Kèké kẹta jáde fún Sebuluni, ní agbo ilé ní agbo ilé
10 Saiu a terceira sorte aos filhos de Zebulom, segundo as suas famílias. O limite da sua herança ia até Saride.
11 Ó sì lọ sí ìwọ̀-oòrùn ní Marala, ó sì dé Dabbeṣeti, ó sì lọ títí dé odo ní ẹ̀bá Jokneamu.
11 O seu limite subia, pelo oeste, a Marala, tocava em Dabesete e chegava até o ribeiro que está diante de Jocneão.
12 Ó sì yípadà sí ìlà-oòrùn láti Saridi sí ìhà ìlà-oòrùn dé ilẹ̀ Kisiloti-Tabori, ó sì lọ sí Daberati, ó sì gòkè lọ sí Jafia.
12 De Saride, voltava para o leste, para o nascente do sol, até o limite de Quislote-Tabor, saía a Daberate, e ia subindo a Jafia;
13 Nígbà náà ní o lọ sí ìhà ìlà-oòrùn lọ sí Gati-Heferi àti Eti-Kaṣini, ó sì jáde ní Rimoni, ó sì yí sí ìhà Nea.
13 dali, passava, para o nascente, a Gate-Hefer, a Ete-Cazim, ia a Rimom, que se estendia até Neá,
14 Ní ibẹ̀, ààlà sì yíká ní ìhà àríwá lọ sí Hnatoni ó sì pín ní àfonífojì Ifita-Eli.
14 e, rodeando-a, o limite passava, para o norte, a Hanatom e terminava no vale de Ifta-El.
15 Lára wọn ni Katati, Nahalali, Ṣimroni, Idala àti Bẹtilẹhẹmu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlá àti ìletò wọn.
15 Ainda Catate, Naalal, Sinrom, Idala e Belém, completando doze cidades com as suas aldeias.
16 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní Sebuluni, ní agbo ilé agbo ilé.
16 Esta era a herança dos filhos de Zebulom, segundo as suas famílias; estas cidades com as suas aldeias.
17 Kèké kẹrin jáde fún Isakari, agbo ilé ní agbo ilé.
17 A quarta sorte saiu a Issacar, aos filhos de Issacar, segundo as suas famílias.
18 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí:
18 O seu território incluía Jezreel, Quesulote, Suném,
19 Hafraimu, Ṣihoni, Anaharati,
19 Hafaraim, Siom, Anacarate,
20 Rabiti, Kiṣioni, Ebesi,
20 Rabite, Quisião, Ebes,
21 Remeti, Eni-Gannimu, Eni-Hada àti Beti-Pasesi.
21 Remete, En-Ganim, En-Hada e Bete-Pasês.
22 Ààlà náà sì dé Tabori, Ṣahasuma, àti Beti-Ṣemeṣi, ó sì pin ní Jordani.
22 O limite tocava o Tabor, Saazima e Bete-Semes e terminava no Jordão. Ao todo, dezesseis cidades com as suas aldeias.
23 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní ẹ̀yà Isakari, ní agbo ilé agbo ilé.
23 Esta era a herança da tribo dos filhos de Issacar, segundo as suas famílias; estas cidades com as suas aldeias.
24 Kèké karùn-ún jáde fún ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
24 Saiu a quinta sorte à tribo dos filhos de Aser, segundo as suas famílias.
25 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí:
25 O seu território incluía Helcate, Hali, Béten, Acsafe,
26 Allameleki, Amadi, àti Miṣali. Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ààlà náà dé Karmeli àti Ṣihori-Libinati.
26 Alameleque, Amade e Misal; e tocava o Carmelo, para o oeste, e Sior-Libnate;
27 Nígbà náà ni o yí sí ìhà ìlà-oòrùn Beti-Dagoni, dé Sebuluni àti àfonífojì Ifita-Eli, ó sì lọ sí àríwá sí Beti-Emeki àti Neieli, ó sì kọjá lọ sí Kabulu ní apá òsì.
27 voltava para o nascente do sol, Bete-Dagom, e tocava Zebulom e o vale de Ifta-El, ao norte de Bete-Emeque e de Neiel, e vinha sair a Cabul, pela esquerda,
28 Ó sì lọ sí Abdoni, Rehobu, Hammoni àti Kana títí dé Sidoni ńlá.
28 Ebrom, Reobe, Hamom e Caná, até a grande Sidom.
29 Ààlà náà sì tẹ̀ sí ìhà Rama, ó sì lọ sí ìlú olódi Tire, ó sì yà sí Hosa, ó sì jáde ní Òkun Ńlá ní ilẹ̀ Aksibu,
29 O limite voltava a Ramá e até a cidade fortificada de Tiro; então tornava a Hosa, para terminar no mar, na região de Aczibe;
30 Uma, Afeki àti Rehobu.
30 também Umá, Afeca e Reobe, completando vinte e duas cidades com as suas aldeias.
31 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
31 Esta era a herança da tribo dos filhos de Aser, segundo as suas famílias; estas cidades com as suas aldeias.
32 Ìpín kẹfà jáde fún Naftali, agbo ilé ní agbo ilé,
32 Saiu a sexta sorte aos filhos de Naftali, segundo as suas famílias.
33 ààlà wọn lọ láti Helefi àti igi ńlá ní Saananimu nímù; kọjá lọ sí Adami Nekebu àti Jabneeli dé Lakkumu, ó sì pín ní Jordani.
33 O seu limite ia desde Helefe, do carvalho em Zaananim, Adami-Nequebe, Jabneel, até Lacum e terminava no Jordão.
34 Ààlà náà gba ìhà ìwọ̀-oòrùn lọ sí Asnoti-Tabori ó sì jáde ní Hukoki. Ó sì dé Sebuluni, ní ìhà gúúsù Aṣeri ní ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Juda ní Jordani ní ìhà ìlà-oòrùn.
34 O limite voltava, pelo oeste, a Aznote-Tabor, de onde passava a Hucoque; tocava Zebulom, ao sul, e Aser, a oeste, e Judá, pelo Jordão, ao nascente do sol.
35 Àwọn ìlú olódi sì Siddimu, Seri, Hamati, Rakàti, Kinnereti,
35 As cidades fortificadas eram Zidim, Zer, Hamate, Racate, Quinerete,
36 Adama, Rama Hasori,
36 Adamá, Ramá, Hazor,
37 Kedeṣi, Edrei, Eni-Aṣọri,
37 Quedes, Edrei, En-Hazor,
38 Ironi, Migdali-Eli, Horemu, Beti-Anati àti Beti-Ṣemeṣi.
38 Irom, Migdal-El, Horém, Bete-Anate e Bete-Semes. Ao todo, dezenove cidades com as suas aldeias.
39 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Naftali, ní agbo ilé sí agbo ilé.
39 Esta era a herança da tribo dos filhos de Naftali, segundo as suas famílias; estas cidades com as suas aldeias.
40 Ìbò kéje jáde fún ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé ní agbo ilé.
40 A sétima sorte saiu à tribo dos filhos de Dã, segundo as suas famílias.
41 Ilẹ̀ ìní wọn nìwọ̀nyí:
41 O território da sua herança incluía Zorá, Estaol, Ir-Semes,
42 Ṣaalabini, Aijaloni, Itila,
42 Saalabim, Aijalom, Itla,
43 Eloni, Timna, Ekroni,
43 Elom, Timna, Ecrom,
44 Elteke, Gibetoni, Baalati,
44 Elteque, Gibetom, Baalate,
45 Jehudu, Bene-Beraki, Gati-Rimoni,
45 Jeúde, Benê-Beraque, Gate-Rimom,
46 Me Jakoni àti Rakkoni, pẹ̀lú ilẹ̀ tí ó kọjú sí Joppa.
46 Me-Jarcom e Racom, com o território diante de Jope.
47 (Ṣùgbọ́n àwọn ará Dani ní ìṣòro láti gba ilẹ̀ ìní wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gòkè lọ, wọ́n sì kọlu Leṣemu, wọ́n sì gbà á, wọ́n sì fi idà kọlù ú, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀. Wọ́n sì ń gbé ní Leṣemu, wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Dani orúkọ baba ńlá wọn).
47 Mas o território dos filhos de Dã era pequeno demais para eles. Por isso os filhos de Dã foram e atacaram Lesém, e a tomaram, matando os moradores a fio de espada. E tomando posse da cidade, foram morar nela e lhe chamaram Dã, segundo o nome de Dã, seu pai.
48 Àwọn ìlú wọ́n yí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé agbo ilé.
48 Esta era a herança da tribo dos filhos de Dã, segundo as suas famílias; estas cidades com as suas aldeias.
49 Nígbà tí wọ́n ti parí pínpín ilẹ̀ náà ní ìpín ti olúkúlùkù, àwọn ará Israẹli fún Joṣua ọmọ Nuni ní ìní ní àárín wọn,
49 Quando acabaram de repartir a terra em herança, segundo os seus territórios, os filhos de Israel deram a Josué, filho de Num, uma herança no meio deles.
50 bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n fún un ni ìlú tí ó béèrè fún, Timnati Serah ní ìlú òkè Efraimu. Ó sì kọ́ ìlú náà, ó sì ń gbé ibẹ̀.
50 Segundo o mandado do Senhor , deram-lhe a cidade que ele havia pedido, Timnate-Sera, na região montanhosa de Efraim. Josué reedificou a cidade e morou nela.
51 Wọ̀nyí ni àwọn ilẹ̀ tí Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti àwọn olórí ẹ̀yà agbo ilé Israẹli fi ìbò pín ní Ṣilo ní iwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Báyìí ni wọ́n parí pínpín ilẹ̀ náà.
51 Estas foram as heranças que Eleazar, o sacerdote, e Josué, filho de Num, e os chefes das famílias repartiram por sorteio, em herança, pelas tribos dos filhos de Israel, em Siló, diante do Senhor , à porta da tenda do encontro. E assim acabaram de repartir a terra.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Josué 19, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.