Josué 19

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Kèké kejì jáde fún ẹ̀yà Simeoni, ní agbo ilé, ní agbo ilé. Ìní wọn sì wà ní àárín ilẹ̀ Juda.
1 E a segunda sorte saiu para Simeão, a saber; para a tribo dos filhos de Simeão, segundo as suas famílias; e a sua herança ficava dentro da herança dos filhos de Judá.
2 Lára ìpín wọn ní:
2 E eles tiveram por herança: Berseba, e Seba, e Molada,
3 Hasari-Ṣuali, Bala, Esemu,
3 e Hazar-Sual, e Balá, e Ezém,
4 Eltoladi, Betuli, Horma,
4 e Eltolade, e Betul, e Horma,
5 Siklagi, Beti-Markaboti, Hasari Susa,
5 e Ziclague, e Bete-Marcabote, e Hazar-Susa,
6 Beti-Lebaoti àti Ṣarueli, ìlú wọn jẹ́ mẹ́tàlá àti ìletò wọn.
6 e Bete-Lebaote, e Saruém: treze cidades e as suas aldeias;
7 Aini, Rimoni, Eteri àti Aṣani, ìlú wọn jẹ́ mẹ́rin àti ìletò wọn,
7 Aim, Rimom, e Eter, e Asã: quatro cidades e as suas aldeias;
8 àti gbogbo àwọn agbègbè ìlú wọ̀nyí títí dé Baalati-Beeri (Rama ní gúúsù).
8 e todas as aldeias que ficavam ao redor destas cidades até Baalate-Ber, Ramá do Sul. Esta é a herança da tribo dos filhos de Simeão, segundo as suas famílias.
9 A mú ogún ìní àwọn ọmọ Simeoni láti ìpín Juda, nítorí ìpín Juda pọ̀ ju èyí tí wọ́n nílò lọ. Báyìí ni àwọn ọmọ Simeoni gba ìní wọn ní àárín ilẹ̀ Juda.
9 Da porção dos filhos de Judá era a herança dos filhos de Simeão; pois a parte dos filhos de Judá lhes era demasiada, por isso os filhos de Simeão tiveram a sua herança dentro da herança daqueles.
10 Kèké kẹta jáde fún Sebuluni, ní agbo ilé ní agbo ilé
10 E a terceira sorte surgiu para os filhos de Zebulom, segundo as suas famílias; e o limite da sua herança ia até Saride.
11 Ó sì lọ sí ìwọ̀-oòrùn ní Marala, ó sì dé Dabbeṣeti, ó sì lọ títí dé odo ní ẹ̀bá Jokneamu.
11 E o seu limite subia em direção ao mar, e Marala, e alcançava Dabesete, e chegava ao rio que está diante de Jocneão.
12 Ó sì yípadà sí ìlà-oòrùn láti Saridi sí ìhà ìlà-oòrùn dé ilẹ̀ Kisiloti-Tabori, ó sì lọ sí Daberati, ó sì gòkè lọ sí Jafia.
12 E, de Saride, voltava-se para o leste, em direção ao sol nascente, até o limite de Quislote-Tabor, e depois sai até Daberate, e sobe até Jafia,
13 Nígbà náà ní o lọ sí ìhà ìlà-oòrùn lọ sí Gati-Heferi àti Eti-Kaṣini, ó sì jáde ní Rimoni, ó sì yí sí ìhà Nea.
13 e de lá passa pelo leste, até Gate-Hefer, para Ete-Cazim, e sai para Rimom-Metoar, para Neá;
14 Ní ibẹ̀, ààlà sì yíká ní ìhà àríwá lọ sí Hnatoni ó sì pín ní àfonífojì Ifita-Eli.
14 e o limite a rodeia pelo lado norte, até Hanatom, e as suas saídas estão no vale de Ifta-El;
15 Lára wọn ni Katati, Nahalali, Ṣimroni, Idala àti Bẹtilẹhẹmu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlá àti ìletò wọn.
15 e Catate, e Naalal, e Sinrom, e Idala, e Belém: doze cidades com as suas aldeias.
16 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní Sebuluni, ní agbo ilé agbo ilé.
16 Esta é a herança dos filhos de Zebulom, segundo as suas famílias, estas cidades com as suas aldeias.
17 Kèké kẹrin jáde fún Isakari, agbo ilé ní agbo ilé.
17 E a quarta sorte surgiu para Issacar, para os filhos de Issacar, segundo as suas famílias.
18 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí:
18 E o seu limite era em direção a Jezreel, e Quesulote, e Suném,
19 Hafraimu, Ṣihoni, Anaharati,
19 e Hafaraim, e Siom, e Anacarate,
20 Rabiti, Kiṣioni, Ebesi,
20 e Rabite, e Quisião, e Ebes,
21 Remeti, Eni-Gannimu, Eni-Hada àti Beti-Pasesi.
21 e Remete, e En-Ganim, e En-Hada, e Bete-Pasês;
22 Ààlà náà sì dé Tabori, Ṣahasuma, àti Beti-Ṣemeṣi, ó sì pin ní Jordani.
22 e o termo alcança Tabor, e Saazima, e Bete-Semes; e as saídas do seu limite eram o Jordão: dezesseis cidades com as suas aldeias.
23 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní ẹ̀yà Isakari, ní agbo ilé agbo ilé.
23 Esta é a herança da tribo dos filhos de Issacar, segundo as suas famílias, as cidades e as suas aldeias.
24 Kèké karùn-ún jáde fún ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
24 E a quinta sorte surgiu para a tribo dos filhos de Aser, segundo as suas famílias.
25 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí:
25 E o seu limite era Helcate, e Hali, e Béten, e Acsafe,
26 Allameleki, Amadi, àti Miṣali. Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ààlà náà dé Karmeli àti Ṣihori-Libinati.
26 e Alameleque, e Amade, e Misal; e alcança o Carmelo, na direção oeste, e Sior-Libnate;
27 Nígbà náà ni o yí sí ìhà ìlà-oòrùn Beti-Dagoni, dé Sebuluni àti àfonífojì Ifita-Eli, ó sì lọ sí àríwá sí Beti-Emeki àti Neieli, ó sì kọjá lọ sí Kabulu ní apá òsì.
27 e se volta para a direção do sol nascente, para Bete-Dagom, e alcança Zebulom, e o vale de Ifta-El em direção ao lado norte de Bete-Emeque, e Neiel, e sai pela esquerda até Cabul,
28 Ó sì lọ sí Abdoni, Rehobu, Hammoni àti Kana títí dé Sidoni ńlá.
28 e Hebrom, e Reobe, e Hamom, e Caná, até a grande Sidom;
29 Ààlà náà sì tẹ̀ sí ìhà Rama, ó sì lọ sí ìlú olódi Tire, ó sì yà sí Hosa, ó sì jáde ní Òkun Ńlá ní ilẹ̀ Aksibu,
29 e depois, o termo se volta a Ramá, e à cidade forte de Tiro; e o termo se volta para Hosa, e as suas saídas estão no mar, desde a costa até Aczibe;
30 Uma, Afeki àti Rehobu.
30 também Umá, e Afeque, e Reobe: vinte e duas cidades com as suas aldeias.
31 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
31 Esta é a herança dos filhos de Aser, segundo as suas famílias, estas cidades com as suas aldeias.
32 Ìpín kẹfà jáde fún Naftali, agbo ilé ní agbo ilé,
32 A sexta sorte surgiu para os filhos de Naftali, a saber, para os filhos de Naftali, segundo as suas famílias.
33 ààlà wọn lọ láti Helefi àti igi ńlá ní Saananimu nímù; kọjá lọ sí Adami Nekebu àti Jabneeli dé Lakkumu, ó sì pín ní Jordani.
33 E o seu termo era de Helefe, desde Alom até Zaananim, e Adami, Nequebe, e Jabneel, até Lacum; e as suas saídas ficavam no Jordão;
34 Ààlà náà gba ìhà ìwọ̀-oòrùn lọ sí Asnoti-Tabori ó sì jáde ní Hukoki. Ó sì dé Sebuluni, ní ìhà gúúsù Aṣeri ní ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Juda ní Jordani ní ìhà ìlà-oòrùn.
34 e depois, o termo se volta para a direção oeste, para Aznote-Tabor, e de lá sai para Hucoque, e alcança Zebulom, no lado sul, e alcança Aser, no lado oeste, e Judá sobre o Jordão, em direção ao sol nascente.
35 Àwọn ìlú olódi sì Siddimu, Seri, Hamati, Rakàti, Kinnereti,
35 E as cidades fortificadas são: Zidim, Zer, e Hamate, Racate, e Quinerete,
36 Adama, Rama Hasori,
36 e Adamá, e Ramá, e Hazor,
37 Kedeṣi, Edrei, Eni-Aṣọri,
37 e Quedes, e Edrei, e En-Hazor,
38 Ironi, Migdali-Eli, Horemu, Beti-Anati àti Beti-Ṣemeṣi.
38 e Irom, e Migdal-El, Horém, e Bete-Anate, e Bete-Semes: dezenove cidades com as suas aldeias.
39 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Naftali, ní agbo ilé sí agbo ilé.
39 Esta é a herança da tribo dos filhos de Naftali, segundo as suas famílias, as cidades e as suas aldeias.
40 Ìbò kéje jáde fún ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé ní agbo ilé.
40 E a sétima sorte surgiu para a tribo dos filhos de Dã, segundo as suas famílias.
41 Ilẹ̀ ìní wọn nìwọ̀nyí:
41 E o termo da sua herança era Zorá, e Estaol, e Ir-Semes,
42 Ṣaalabini, Aijaloni, Itila,
42 e Saalabim, e Aijalom, e Itla,
43 Eloni, Timna, Ekroni,
43 e Elom, e Timna, e Ecrom,
44 Elteke, Gibetoni, Baalati,
44 e Elteque, e Gibetom, e Baalate,
45 Jehudu, Bene-Beraki, Gati-Rimoni,
45 e Jeúde, e Benê-Beraque, e Gate-Rimom,
46 Me Jakoni àti Rakkoni, pẹ̀lú ilẹ̀ tí ó kọjú sí Joppa.
46 e Me-Jarcom, e Racom, com o limite na frente de Jafo.
47 (Ṣùgbọ́n àwọn ará Dani ní ìṣòro láti gba ilẹ̀ ìní wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gòkè lọ, wọ́n sì kọlu Leṣemu, wọ́n sì gbà á, wọ́n sì fi idà kọlù ú, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀. Wọ́n sì ń gbé ní Leṣemu, wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Dani orúkọ baba ńlá wọn).
47 E o termo dos filhos de Dã lhes saiu demasiado pequeno; por isso os filhos de Dã subiram para lutar contra Lesém, e a tomaram, e a feriram com o fio da espada, e a possuíram, e habitaram nela, e chamaram Lesém de Dã, segundo o nome de Dã, o seu pai.
48 Àwọn ìlú wọ́n yí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé agbo ilé.
48 Esta é a herança da tribo dos filhos de Dã, segundo as suas famílias, estas cidades com as suas aldeias.
49 Nígbà tí wọ́n ti parí pínpín ilẹ̀ náà ní ìpín ti olúkúlùkù, àwọn ará Israẹli fún Joṣua ọmọ Nuni ní ìní ní àárín wọn,
49 Quando eles terminaram de dividir a terra de herança pelos seus termos, os filhos de Israel deram uma herança a Josué, o filho de Num, no meio deles;
50 bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n fún un ni ìlú tí ó béèrè fún, Timnati Serah ní ìlú òkè Efraimu. Ó sì kọ́ ìlú náà, ó sì ń gbé ibẹ̀.
50 segundo a palavra do SENHOR eles lhe deram a cidade que pediu, a saber Timnate-Sera no monte Efraim; e ele edificou a cidade, e nela habitou.
51 Wọ̀nyí ni àwọn ilẹ̀ tí Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti àwọn olórí ẹ̀yà agbo ilé Israẹli fi ìbò pín ní Ṣilo ní iwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Báyìí ni wọ́n parí pínpín ilẹ̀ náà.
51 Estas são as heranças que Eleazar, o sacerdote, e Josué, o filho de Num, e os cabeças dos pais das tribos dos filhos de Israel, dividiram como herança, por sorteio, em Siló, diante do SENHOR, à porta do tabernáculo da congregação. Assim, eles terminaram de dividir a região.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Josué 19, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.